Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 5

Ìwé kíkà ti n

1 Nígbà náà ni mo yípadà, mo gbé ojú mi sókè, mo , kíyèsi i, ìwé kíká ti ń .

2 Ó fún mi , "ni ìwọ ?"

Èmi dáhùn , "Mo ìwé kíká ń ; gígùn rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá."

3 Ó fún mi , "Èyí ni ègún ó jáde lọ gbogbo ilẹ̀ ayé, nítorí gbogbo àwọn ó jalè ni a ó kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀; gbogbo àwọn ó búra èké ni a ó kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀. 4 Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Èmi yóò un jáde, Èmi yóò si wọ inú ilé olè lọ, àti inú ilé ẹni ti o fi orúkọ mi búra èké, yóò si ni àárín ilé rẹ̀, yóò si rún pẹ̀igi àti òkúta inú rẹ̀.’ "

Obìnrin nínú agbọ̀n

5 Angẹli ń mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, ó fún mi , "Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, o wo nǹkan yóò jáde lọ."

6 Mo , "ni nǹkan náà?"

Ó , "Èyí ni òsùwọ̀n ó jáde lọ." Ó , "Èyí ni àwòrán gbogbo ilẹ̀ ayé."

7 kíyèsi i, a gbé tálẹ́ǹtì òjé sókè, obìnrin kan nìyìí ó jókòó àárín àpẹẹrẹ òsùwọ̀n. 8 Ó , "Èyí ni ìwà búburú." Ó ti àárín òsùwọ̀n, ó ju ìdérí òjé ẹnu rẹ̀.

9 Mo gbé ojú mi sókè, mo , kíyèsi i, obìnrin méjì jáde , ̀fúùfù nínú ìyẹ́ wọn; nítorí wọ́n ìyẹ́ ìyẹ́ àkọ̀, wọ́n gbé àpẹẹrẹ òsùwọ̀n náà àárín méjì ayé àti ̀run.

10 Mo sọ fún angẹli ó ń mi sọ̀rọ̀ , "Níbo ni àwọn wọ̀nyí ń gbé òsùwọ̀n náà lọ."

11 Ó si fún mi , "orílẹ̀-èdè Babeli láti kọ ilé fún un. ó ṣetán, a ó fi ìdí rẹ̀ mulẹ̀, a o fi ka orí ìpìlẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também