Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 2

Okùn ìwọ̀n ti Jerusalẹmu

1 si tún gbé ojú mi, sókè, mo , kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀. 2 Mo , "Níbo ni ìwọ ń lọ?"

O fún , "Láti wọn Jerusalẹmu, láti iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀."

3 kíyèsi i, angẹli ó ń mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀. 4 Ó si fún un , "Sáré, sọ fún ̀dọ́mọkùnrin yìí , A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti odi, nítorí ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ̀sìn inú rẹ̀. 5 Olúwa : Èmi ó jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’

6 "! ! kúrò ni ilẹ̀ àríwá," ni Olúwa , "nítorí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ̀run ni mo yín káàkiri," ni Olúwa .

7 "Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ ó ń ọmọbìnrin Babeli gbé." 8 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi àwọn orílẹ̀-èdè ń yin: nítorí ẹni ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀. 9 Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi orí wọn, wọn yóò jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ̀yin yóò mọ̀ , Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.

10 "Kọrin o yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti èmi yóò gbé àárín rẹ," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . 11 "̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ọjọ́ náà, wọn yóò di ènìyàn mi, èmi yóò gbé àárín rẹ, ìwọ yóò mọ̀ , Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi . 12 Olúwa yóò jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò tún yan Jerusalẹmu. 13 2.13: Hk 2.20; Sf 1.7.̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também