Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 3

Aṣọ mímọ́ fún olórí àlùfáà

1 Ó fi Joṣua olórí àlùfáà hàn , ó dúró níwájú angẹli Olúwa, Satani dúró lọ́wọ́ ̀tún rẹ̀ láti kọjú ìjà i. 2 3.2: Jd 9.Olúwa si fún Satani , "Olúwa ìwọ Satani; àní Olúwa ó ti yan Jerusalẹmu, , igi iná kọ́ ni èyí a kúrò nínú iná?"

3 A wọ Joṣua ni aṣọ èérí, ó dúró níwájú angẹli náà. 4 Ó dáhùn ó fún àwọn ó dúró níwájú rẹ̀ , "Bọ́ aṣọ èérí kúrò ara rẹ̀."

Ó fún Joṣua , "ó, mo àìṣedéédéé rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, èmi yóò wọ̀ ́ aṣọ ̀yẹ."

5 , "Jẹ wọn fi gèlè mímọ́ e lórí." Wọn fi gèlè mímọ́ e lórí, wọn fi aṣọ wọ̀ ́. Angẹli Olúwa dúró í.

6 Angẹli Olúwa tẹnumọ́ ọn fún Joṣua : 7 "Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : ìwọ ́ rìn ̀mi, ìwọ yóò pa àṣẹ mi mọ́, ìwọ yóò ṣe ìdájọ́ ilé mi pẹ̀, ìwọ yóò ṣe àkóso ààfin mi, èmi yóò fún ààyè láti rìn láàrín àwọn ó dúró yìí.

8 " 3.8: Isa 4.2; Jr 23.5; 33.15; Sk 6.12.Gbọ́, ìwọ Joṣua olórí àlùfáà, ìwọ, àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ ó jókòó níwájú rẹ: nítorí ẹni ìyanu ni wọ́n: nítorí kíyèsi i, èmi yóò ̀ka náà fun ìránṣẹ́ mi. 9 Nítorí kíyèsi i, òkúta mo gbé kalẹ̀ níwájú Joṣua; lórí òkúta kan ni ojú méje : kíyèsi i, èmi yóò fín àkọlé rẹ̀,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Èmi yóò ̀bi ilẹ̀ náà kúrò ọjọ́ kan.

10 3.10: Mt 4.4. " Olúwa àwọn ọmọ-ogun , ọjọ́ náà ni olúkúlùkù yóò pe ẹnìkejì láti jókòó rẹ̀ sábẹ́ igi àjàrà àti sábẹ́ igi ̀pọ̀tọ́.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também