Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 6

Kẹ̀kẹ́ ogun mẹ́rin ìdájọ́ Ọlọ́run

1 6.1-3: If 6.2-8. Mo yípadà, mo gbé ojú mi sókè, mo , kíyèsi i, kẹ̀kẹ́ mẹ́rin jáde láti àárín òkè ńlá méjì, àwọn òkè ńlá náà jẹ́ òkè ńlá idẹ. 2 Àwọn ẹṣin pupa kẹ̀kẹ́ èkínní; àti àwọn ẹṣin dúdú kẹ̀kẹ́ èkejì. 3 Àti àwọn ẹṣin funfun kẹ̀kẹ́ ̀kẹta; àti àwọn adíkálà àti alágbára ẹṣin kẹ̀kẹ́ ̀kẹrin. 4 Mo dáhùn, mo béèrè lọ́wọ́ angẹli ń mi sọ̀rọ̀ , "ni ìwọ̀nyí, olúwa mi."

5 6.5: If 7.1. Angẹli náà si dáhùn ó fún mi , "Wọ̀nyí ni àwọn ̀mẹ́rin ti ̀run, wọn ń lọ kúrò lẹ́yìn wọ́n ti fi ara wọn hàn níwájú Olúwa gbogbo ayé. 6 Àwọn ẹṣin dúdú ó nínú rẹ̀ jáde lọ ilẹ̀ àríwá; àwọn funfun jáde lọ si ìwọ̀-oòrùn; àwọn adíkálà jáde lọ ìhà ilẹ̀ gúúsù."

7 Àwọn alágbára ẹṣin jáde lọ, wọ́n ń ̀àti lọ wọn a rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ni ayé; ó , "lọ, lọ rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ayé!" Wọ́n rín síyìn-ín sọ́hùn-ún ayé.

8 Nígbà náà ni ohùn kan mi, ó mi sọ̀rọ̀ , "ó, àwọn wọ̀nyí ó lọ síhà ilẹ̀ àríwá ti ̀mi parọ́rọ́ ni ilẹ̀ àríwá."

Adé fún Joṣua

9 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , : 10 "nínú ìgbèkùn, nínú àwọn Heldai, Tobiah, àti ti Jedaiah, ó ti Babeli , ìwọ ọjọ́ kan náà, o wọ ilé Josiah ọmọ Sefaniah lọ. 11 o fàdákà àti wúrà, o fi ṣe adé púpọ̀, gbé wọn ka orí Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà. 12 6.12: Sk 3.8; Isa 4.2; Jr 23.5; 33.15.sọ fún un , Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ , wo ọkùnrin náà ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ ̀ka; yóò yọ ̀ka láti abẹ́ rẹ̀ , yóò si kọ́ tẹmpili Olúwa wa. 13 Òun ni yóò kọ́ tẹmpili Olúwa òun ni yóò wọ̀ ògo, yóò jókòó, yóò jẹ ọba lórí ìtẹ́ rẹ̀; òun ó jẹ́ àlùfáà lórí ìtẹ́ rẹ̀; ìmọ̀ àlàáfíà yóò láàrín àwọn méjèèjì.14 Adé wọ̀nyí yóò fún Helemu àti fún Tobiah, àti fún Jedaiah, àti fún Heni ọmọ Sefaniah fún ìrántí ni tẹmpili Olúwa. 15 Àwọn ó jìnnà réré yóò láti kọ́ tẹmpili Olúwa, ̀yin yóò mọ̀ , Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti rán mi yín. Yóò bẹ́̀ ̀yin yóò gbà ohùn Olúwa, Ọlọ́run yín gbọ́ nítòótọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também