Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 28

Ọrẹ ojoojúmọ́

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Fún àwọn ọmọ Israẹli òfin yìí o fún wọn : i gbé e iwájú mi àkókò a ti yàn, oúnjẹ ọrẹ ẹbọ mi a fi iná ṣe mi, gẹ́gẹ́ òórùn dídùn mi.3 28.3-8: Ek 29.38-42.Sọ fún wọn, Èyí ọrẹ ẹbọ a fi iná sun gbọdọ̀ fún Olúwa: akọ ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan aláìlábàwọ́n gẹ́gẹ́ ẹbọ sísun ojoojúmọ́. 4 Pèsè ̀dọ́-àgùntàn kan òwúrọ̀ àti òmíràn àfẹ̀mọ́júmọ́. 5 Pẹ̀ẹbọ ohun jíjẹ ó jẹ́ ìdámẹ́wàá efa ìyẹ̀fun dáradára a mọ́ ìdámẹ́rin hínì òróró a yọ lára Olifi. 6 Èyí ni ẹbọ sísun gbogbo ìgbà a fi lélẹ̀ òkè Sinai gẹ́gẹ́ olóòórùn dídùn ẹbọ a fi iná sun fún Olúwa pẹ̀iná. 7 Àfikún ọrẹ ohun mímu rẹ gbọdọ̀ jẹ́ ìdámẹ́rin ti hínì dídé omi mímu ó kan pẹ̀̀kọ̀̀kan ̀dọ́-àgùntàn. Da ẹbọ mímu náà síta Olúwa ibi mímọ́. 8 Pèsè ̀dọ́-àgùntàn kejì àfẹ̀mọ́júmọ́, pẹ̀oríṣìí ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu èyí ó pèsè òwúrọ̀, èyí ni ẹbọ a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn Olúwa.

Ẹbọ ọjọ́ ìsinmi

9 " ọjọ́ ìsinmi, pèsè akọ ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan lábùkù, pẹ̀ẹbọ ohun mímu àti ẹbọ ohun jíjẹ i ṣe ìdá méjì nínú ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun a fi òróró . 10 Èyí ni ẹbọ sísun fún gbogbo ọjọ́ ìsinmi kọ̀̀kan, àfikún pẹ̀ẹbọ sísun àti ẹbọ ohun mímu.

Ẹbọ oṣooṣù

11 " Àti ọjọ́ o bẹ̀rẹ̀ oṣù kọ̀̀kan, ̀yin ó gbé ẹbọ sísun fún Olúwa pẹ̀̀dọ́ akọ màlúù méjì, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀̀kan, gbogbo rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù. 12 Pẹ̀akọ màlúù kọ̀̀kan ni wọn ó ẹbọ ohun jíjẹ ẹbọ ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá ìyẹ̀fun a pòpọ̀ pẹ̀òróró; pẹ̀àgbò, ni wọn ó ẹbọ ohun jíjẹ í ṣe ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun a pòpọ̀ mọ́ òróró; 13 pẹ̀̀kọ̀̀kan ̀dọ́-àgùntàn, ni ẹbọ ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná a mọ́ òróró. Èyí ni ẹbọ sísun, òórùn dídùn, àti ẹbọ a ṣe fún Olúwa pẹ̀iná. 14 ẹbọ ohun mímu wọn jẹ́ ààbọ̀ òsùwọ̀n hínì ti ọtí wáìnì, fún akọ màlúù kan, àti ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n hínì fún àgbò kan àti ìdámẹ́rin òsùwọ̀n hínì fún ̀dọ́-àgùntàn kan. Èyí ni ẹbọ sísun wọn ó máa oṣù kọ̀̀kan nínú ọdún. 15 Yàtọ̀ ẹbọ sísun pẹ̀ẹbọ ohun mímu, gbọdọ̀ fi akọ ewúrẹ́ kọ̀̀kan fún Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀.

Àjọ ìrékọjá

16 28.16: Ek 12.1-14,21-27; Le 23.5; De 16.1,2,5-7. " ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní ni ìrékọjá Olúwa gbọdọ̀ wáyé. 17 28.17-25: Ek 12.15-20; Le 23.6-8; De 16.3,4,8.ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù yìí gbọdọ̀ ṣiṣẹ́ àjọ̀dún fún ọjọ́ méje ó jẹ àkàrà ìwúkàrà. 18 ọjọ́ kìn-ín-ní àpéjọ mímọ́ ó ; ́yin gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ agbára kankan. 19 ẹbọ sísun Olúwa, u pẹ̀̀dọ́ màlúù méjì akọ, ẹbọ sísun pẹ̀iná àgbò kan àti ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀̀kan wọn ó jẹ́ aláìlábùkù. 20 Pẹ̀akọ màlúù kọ̀̀kan ni pèsè ẹbọ ohun mímu pẹ̀ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá ìyẹ̀fun kíkúnná a fi òróró ; pẹ̀àgbò, ìdá méjì nínú mẹ́wàá; 21 pẹ̀̀dọ́-àgùntàn kọ̀̀kan ìdákan nínú mẹ́wàá. 22 Pẹ̀òbúkọ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ láti ṣètùtù fún un yín. 23 Ṣe eléyìí àfikún ẹbọ sísun àràárọ̀. 24 Báyìí ̀yin rúbọ ọjọọjọ́, jálẹ̀ ọjọ́ méjèèje, oúnjẹ ẹbọ a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn Olúwa; ó u pẹ̀ẹbọ sísun ìgbà gbogbo, àti ẹbọ ohun mímu. 25 ọjọ́ keje ̀yin ó àpéjọ mímọ́, gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.

Àjọ ̀sọ̀̀sẹ̀

26 28.26-31: Ek 23.16; 34.22; Le 23.15-21; De 16.9-12. " ọjọ́ àkọ́so pẹ̀, nígbà ̀yin ẹbọ ohun jíjẹ tuntun fún Olúwa lẹ́yìn àsìkò àjọ̀dún, ̀yin ó àpéjọ mímọ́, ̀yin gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. 27 ẹbọ sísun ẹgbọrọ màlúù méjì, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kan gẹ́gẹ́ òórùn dídùn fún Olúwa. 28 Pẹ̀̀kọ̀̀kan akọ màlúù ẹbọ ohun mímu ìdámẹ́ta pẹ̀òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná a fi òróró pẹ̀àgbò kan. 29 Àti pẹ̀̀kọ̀̀kan ̀dọ́-àgùntàn méje, ó jẹ́ ìdákan nínú mẹ́wàá. 30 fi òbúkọ kan ṣe ètùtù fún ara yín. 31 ̀yin ó wọn pẹ̀ẹbọ sísun ìgbà gbogbo, àti ẹbọ ohun mímu yín àti ẹbọ ohun jíjẹ yín. ri dájú àwọn ẹranko náà jẹ́ aláìlábùkù.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também