Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 15

Àwọn ọrẹ àfikún

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , Nígbà ilẹ̀ èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ ibùgbé 3 ̀yin ó ṣe ẹbọ iná Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ̀wọ́ ẹran, 4 nígbà náà ni ẹni ó ọrẹ rẹ̀ , yóò tún ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró síwájú Olúwa. 5 Pẹ̀̀dọ́-àgùntàn kọ̀̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ ohun mímu.

6 " Fún àgbò kan ni pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró . 7 Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ òórùn dídùn Olúwa.

8 " Nígbà pèsè ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà Olúwa, 9 ẹni náà yóò ̀dọ́ akọ màlúù náà pẹ̀ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró . 10 ó tún ìdajì òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn Olúwa. 11 Báyìí ni ṣe pèsè ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́. 12 ṣe bẹ́̀ fún ̀kọ̀̀kan wọn, iyekíye ̀yin ìbá à pèsè.

13 " Ẹnikẹ́ni ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà ó ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ òórùn dídùn fún Olúwa. 14 15.14: Ek 12.49; Le 24.22; Nu 15.15,16,29.àlejò kan ń gbé láàrín yín gbogbo ìran yín, irú ẹni bẹ́̀ fẹ́ ọrẹ àfinásun òórùn dídùn fún Olúwa, gbogbo ṣe ń ṣe náà ni ó ṣe. 15 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran ń bọ̀. ̀yin àti àlejò ń gbé láàrín yín jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa. 16 Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò fún yín àti fún àwọn àlejò ń gbé láàrín yín.’ "

17 15.17-21: El 34.26; Le 23.14. Olúwa sọ fún Mose , 18 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , Nígbà ilẹ̀ mo ń yín lọ. 19 jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọrẹ ìgbésókè fún Olúwa. 20 àkàrà nínú àkọ́so oúnjẹ yín gẹ́gẹ́ ọrẹ ìgbésókè Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín. 21 Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni ti máa ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.

Ọrẹ fún àwọn ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀

22 15.22-26: Le 4.13-21. " kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin Olúwa fún Mose mọ́, 23 èyí ni gbogbo òfin Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ Olúwa ti fún yín àti títí ìran ń bọ̀. 24 ̀ṣẹ̀ wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ ìjọ ènìyàn mọ̀ i, nígbà náà ni gbogbo ìjọ ènìyàn ̀dọ́ akọ màlúù kan fún ẹbọ sísun òórùn dídùn Olúwa, pẹ̀ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ ìlànà, pẹ̀akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. 25 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó dáríjì wọ́n, nítorí ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n ti ọrẹ àfinásun fún Olúwa nítorí ̀ṣẹ̀ wọ́n ṣẹ̀. 26 A ó dárí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì ń gbé àárín wọn nítorí àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ̀ṣẹ̀ náà.

27 15.27-29: Le 4.2-12. " Ṣùgbọ́n ó jẹ́ ẹnìkan sẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, ó abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. 28 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, wọ́n ṣe ètùtù fún un, a ó dáríjì í. 29 Òfin kan ̀yin ó fún ẹnikẹ́ni ṣẹ̀ àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni a nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò ń ṣe àtìpó.

30 " Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni mọ̀ ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́̀ ti ̀gàn orúkọ Olúwa, a ó irú ẹni bẹ́̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀. 31 Nítorí ẹni náà ti kẹ́gàn ̀rọ̀ Olúwa ó ti òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ irú ẹni bẹ́̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ̀bi rẹ̀ yóò lórí rẹ̀.’ "

Ìjìyà fún rírú òfin ọjọ́ ìsinmi

32 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli nínú aginjù, wọ́n ọkùnrin kan ń ṣá igi ọjọ́ Ìsinmi. 33 Àwọn i níbi ti ń ṣá igi wọ́n un ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn, 34 wọ́n fi ìpamọ́ nítorí ohun wọn ó ṣe fún un ì wọn. 35 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Kíkú ni ọkùnrin náà yóò gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ́ lókùúta pa ̀yìn ibùdó." 36 Wọ́n un jáde ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sọ ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Wajawaja lára aṣọ

37 Olúwa sọ fún Mose , 38 15.38-40: De 22.12."àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, o sọ fún wọn : Títí àwọn ìran ń bọ̀ ni wọn máa ṣe wajawaja etí aṣọ wọn, wọn fi okùn tẹ́́rẹ́ aláwọ̀ búlúù wajawaja kọ̀̀kan. 39 Wajawaja yìí ni máa wọ̀ láti yín rántí gbogbo òfin Olúwa, à ṣe wọ́n, à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀ìfẹ́kúfẹ̀́ ọkàn àti ojú yín. 40 Nígbà náà ni ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ó jẹ́ mímọ́ Ọlọ́run yín. 41 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín ó yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também