Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 21

A pa ìlú Aradi run

1 21.1: Nu 33.40. Nígbà ọba Aradi ará Kenaani, ń gbé gúúsù gbọ́ Israẹli ń bọ̀ ojú ̀Atarimu, ó Israẹli ó fi agbára díẹ̀ lára wọn. 2 Nígbà náà ni Israẹli jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa , "o fi àwọn ènìyàn yìí wa lọ́wọ́, gbogbo ìlú wọn ni a ó parun." 3 Olúwa gbọ́ ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, ó fi àwọn ará Kenaani wọn lọ́wọ́. Wọ́n pa wọ́n run pátápátá; torí náà ni a ṣe ń pe ibẹ̀ Horma.

Ejò idẹ

4 Wọ́n rin ìrìnàjò láti òkè Hori lọ ̀lọ Òkun Pupa, láti kọjá yípo Edomu. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn bínú ojú ̀; 5 wọ́n sọ̀rọ̀ lòdì Ọlọ́run àti Mose, wọ́n , "Èéṣe ìwọ fi wa jáde láti Ejibiti a ba le aginjù yìí? oúnjẹ! omi! Àwa kórìíra oúnjẹ dára yìí!"

6 Nígbà náà ni Olúwa rán ejò olóró àárín wọn; wọ́n àwọn ènìyàn jẹ, ̀pọ̀ àwọn ọmọ Israẹli . 7 Àwọn ènìyàn ̀dọ̀ Mose wọn , "A ti ̀ṣẹ̀ nígbà asọ̀rọ̀-òdì Olúwa àti ìwọ pẹ̀. Gba àdúrà Olúwa ejò náà kúrò lọ́dọ̀ wa." Nígbà náà ni Mose gbàdúrà fún àwọn ènìyàn.

8 Olúwa sọ fún Mose , "Rọ ejò, a ó gbé e kọ́ sókè lórí igi, ẹni ejò ti jẹ ó yóò ." 9 Nígbà náà ni Mose rọ ejò onírin ó gbé e kọ́ sórí igi, ejò bu ẹnikẹ́ni jẹ ó ti ó yóò .

Ìrìnàjò Moabu

10 Àwọn ọmọ Israẹli tẹ̀síwájú wọ́n péjọ Obotu. 11 Wọ́n gbéra Obotu wọ́n pa ibùdó Iye-Abarimu, aginjù ó kọjú Moabu ìdojúkọ ìlà-oòrùn. 12 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti gbéra wọ́n pa ibùdó àfonífojì Seredi. 13 Láti ibẹ̀ lọ, wọn ṣí, wọ́n ìhà kejì Arnoni, ó aginjù ó agbègbè ilẹ̀ àwọn ọmọ Amori. Arnoni jẹ́ ààlà fún ilẹ̀ Moabu, láàrín Moabu àti Amori. 14 Ìdí nìyìí ìwé ogun Olúwa se ,

"Wahebu Sufa, Òkun Pupa àti

odò Arnoni 15 àti ìṣàn odò

ó darí ibùjókòó Ari

ó fi ara ti ìpínlẹ̀ Moabu."

16 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ rìn Beeri, èyí ni kànga Olúwa sọ fún Mose, "àwọn ènìyàn jọ èmi ó fún wọn omi."

17 Nígbà náà ni Israẹli kọ orin yìí ,

"Sun jáde, ìwọ kànga!

máa kọrin nípa rẹ̀,

18 nípa kànga àwọn ọmọ-aládé gbẹ́,

nítorí àwọn ọlọ́ènìyàn ni ó gbẹ́ ;

àwọn ọlọ́àwọn ènìyàn fi ̀aládé àti ̀oyè wọn gbẹ́."

Nígbà náà wọ́n kúrò láti aginjù lọ Mattana, 19 láti Mattana lọ Nahalieli, láti Nahalieli lọ Bamoti, 20 àti láti Bamoti lọ àfonífojì Moabu níbi òkè Pisga, ó òkè ilé omi ti kọjú aginjù.

Ìṣẹ́gun Sihoni àti Ogu

21 21.21-30: De 2.26-37. Israẹli rán oníṣẹ́ láti sọ fún Sihoni ọba àwọn ará Amori ,

22 "Jẹ́ a kọjá orílẹ̀-èdè rẹ. A kọjá inú oko pápá tàbí ọgbà àjàrà àbí mu omi láti inú kànga. A máa gba òpópónà náà ti ọba títí a ó fi la ilẹ̀ rẹ kọjá."

23 Ṣùgbọ́n Sihoni jẹ́ àwọn Israẹli kọjá ilẹ̀ wọn. Ó pe àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jọ wọ́n wọ́de ogun lọ aginjù nítorí àwọn ọmọ Israẹli. Nígbà ó Jahasi, ó àwọn ọmọ Israẹli . 24 Àmọ́, Israẹli ṣẹ́gun, wọn fi ojú idà pa wọ́n, wọ́n gba ilẹ̀ láti ọwọ́ Arnoni lọ Jabbok, títí ó fi ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, nítorí ààlà wọn jẹ́ olódi. 25 Israẹli gba gbogbo ìlú Amori wọ́n ń gbé ibẹ̀ pẹ̀Heṣboni, àti gbogbo ibùgbé ìlú i . 26 Heṣboni ni ìlú Sihoni ọba àwọn ará Amori, ẹni ó ọba Moabu ti tẹ́lẹ̀ ó gba gbogbo ilẹ̀ rẹ̀ ọwọ́ rẹ̀ títí Arnoni.

27 Ìdí nìyìí akọrin sọ ,

"Heṣboni jẹ́ a tún un kọ́;

jẹ́ ìlú Sihoni padà bọ̀ sípò.

28 "Iná jáde láti Heṣboni,

̀wọ́-iná láti Sihoni.

Ó Ari àti Moabu run,

àti ìlú àwọn olùgbé ibi gíga Arnoni.

29 Ègbé fún , ìwọ Moabu!

ti parun, ̀yin ènìyàn Kemoṣi!

Ó ti fi ọmọ rẹ̀ ọkùnrin sílẹ̀ gẹ́gẹ́ ìsáǹsá

àti ọmọ rẹ̀ obìnrin gẹ́gẹ́ ìgbèkùn

fún Sihoni ọba àwọn Amori.

30 "Ṣùgbọ́n àti wọ́n ṣubú;

a ti pa ìjẹgàba Heṣboni run, a pa wọ́n run títí Diboni.

A ti wọ́n lulẹ̀ títí Nofa,

ó fi Medeba."

31 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli ń gbé ilẹ̀ Amori.

32 Lẹ́yìn ìgbà Mose rán ayọ́lẹ̀lọ Jaseri, àwọn ọmọ Israẹli gba àwọn agbègbè wọn wọ́n àwọn Amori níbẹ̀ jáde. 33 21.33-35: De 3.1-7.Nígbà náà wọ́n pẹ̀yìndà wọ́n gòkè lọ Baṣani, Ogu ọba ti Baṣani àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun ó wọ́de ogun jáde láti pàdé wọn ojú ogun Edrei.

34 Olúwa sọ fún Mose , "ṣe bẹ̀rẹ̀, nítorí fi òun lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀, ìwọ ó ṣe i gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe Sihoni ọba Amori ẹni ó ń jẹ ọba Heṣboni."

35 Wọ́n pa á, pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, wọn fi ku ẹnìkan fún un láàyè. Wọ́n gba ìní ilẹ̀ rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também