Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 19

Omi Ìwẹ̀nùmọ́

1 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 2 "Èyí ni ohun òfin Olúwa pàṣẹ béèrè lọ́wọ́ yín. Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, wọn ẹgbọrọ ̀dọ́ màlúù pupa lábùkù tàbí àbàwọ́n, lára èyí a ì di àjàgà mọ́. 3 fún Eleasari àlùfáà, yóò mu jáde lọ ̀yìn ibùdó ó pa á ojú rẹ. 4 Nígbà náà ni Eleasari àlùfáà yóò lára ̀jẹ̀ rẹ̀ sórí ìka ọwọ́ rẹ̀ yóò wọn lẹ́̀méje ̀kánkán iwájú àgọ́ ìpàdé. 5 ojú rẹ̀ ni àlùfáà yóò ti sun ̀dọ́ abo màlúù yìí: awọ ara rẹ̀, ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹran-ara àti ìgbẹ́ rẹ̀. 6 Àlùfáà yóò igi kedari, hísópù àti òwú òdòdó yóò wọ́n àárín ̀dọ́ abo màlúù a ń sun. 7 Lẹ́yìn náà, àlùfáà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ ara rẹ̀ pẹ̀omi lẹ́yìn náà ó sínú àgọ́. Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 8 Ẹni ó sun ún náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀ pẹ̀omi, òun náà yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

9 "Ẹni mímọ́ ni yóò eérú ̀dọ́ màlúù náà lọ ibi a mímọ́ lẹ́yìn ibùdó. gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli o pamọ́ fún lílò fún omi ìwẹ̀nùmọ́. Ó jẹ́ ìwẹ̀nùmọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀. 10 Ọkùnrin ó eérú ̀dọ́ abo màlúù náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, òun náà yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà láéláé fún àwọn ọmọ Israẹli àti fún àwọn àjèjì ó ń gbé láàrín wọn.

11 "Ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kan òkú ẹnikẹ́ni, yóò jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ méje. 12 Ó gbọdọ̀ wẹ ara rẹ̀ pẹ̀omi ọjọ́ kẹta àti ọjọ́ keje; nígbà náà ni yóò jẹ́ mímọ́. Ṣùgbọ́n ó jẹ́ wẹ ara rẹ̀ mọ́ ọjọ́ kẹta àti ọjọ́ keje yóò jẹ́ aláìmọ́. 13 Ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kan òkú ẹnìkan wẹ ara rẹ̀ mọ́, ó ba àgọ́ Olúwa jẹ́. A ó irú ẹni bẹ́̀ kúrò lára àwọn ọmọ Israẹli. Nítorí a ì wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ e lórí, ó jẹ́ aláìmọ́, àìmọ́ rẹ̀ lára rẹ̀.

14 "Èyí ni òfin ó jẹ mọ́ ènìyàn nínú àgọ́, ẹnikẹ́ni ó wọ inú àgọ́ àti ẹni ó nínú àgọ́ yóò di aláìmọ́ fún ọjọ́ méje, 15 gbogbo ohun èlò a fi omọrí ni yóò jẹ́ aláìmọ́.

16 "Ẹnikẹ́ni ó ìta ó fi ọwọ́ kan ẹni a fi idà pa tàbí ẹni ó ikú àtọ̀runwá, tàbí ẹnìkan fi ọwọ́ kan egungun òkú ènìyàn tàbí isà òkú, yóò jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ méje.

17 "Fún aláìmọ́ ènìyàn, eérú díẹ̀ lára eérú ọrẹ ìwẹ̀nùmọ́ sínú ìgò, o da omi ń sàn e lórí. 18 Nígbà náà, ọkùnrin a mímọ́ yóò hísópù díẹ̀ yóò í sínú omi yóò fi wọ́n àgọ́ àti gbogbo ohun èlò a ṣe lọ́ṣọ̀́ àti àwọn ènìyàn ó níbẹ̀. O gbọdọ̀ tún fi wọ́n ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kan egungun òkú ènìyàn tàbí isà òkú, tàbí ẹni ó ikú ara rẹ̀, tàbí ẹni ó ikú àti ̀run . 19 Ọkùnrin ó mọ́ ni ó bu omi wọ́n àwọn ènìyàn aláìmọ́ ọjọ́ kẹta àti ọjọ́ keje, ọjọ́ keje ó gbọdọ̀ wẹ ara rẹ̀ mọ́. Ẹni a wẹ̀mọ́ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀ pẹ̀omi, ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà yóò mọ́. 20 Ṣùgbọ́n ẹni ó jẹ́ aláìmọ́ wẹ ara rẹ̀ mọ́, a gbọdọ̀ e kúrò nínú ìjọ ènìyàn, nítorí ó ti ba àgọ́ Olúwa jẹ́. A ì fi omi ìwẹ̀nùmọ́ ara rẹ̀, ó jẹ́ aláìmọ́. 21 Èyí jẹ́ ìlànà láéláé fún wọn.

"Ọkùnrin ó wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ àti ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kan omi ìwẹ̀nùmọ́ yóò di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. 22 Gbogbo ohun ẹni ó jẹ́ aláìmọ́ fi ọwọ́ kàn yóò di àìmọ́, ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kàn án yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também