Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 26

Ìkànìyàn ẹlẹ́̀kejì

1 26.1-51: Nu 1.1-46. Lẹ́yìn àjàkálẹ̀-ààrùn Olúwa sọ fún Mose àti Eleasari ọmọ Aaroni, àlùfáà , 2 "Ka iye gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ ìdílé wọ́n; láti ẹni ogun ọdún àti bẹ́̀ lọ ó lójú ogun Israẹli." 3 Lórí pẹ̀tẹ́lẹ̀ ti Moabu pẹ̀Jordani ó kọjá Jeriko, Mose àti Eleasari àlùfáà sọ̀rọ̀ pẹ̀wọn ó , 4 "Ka iye àwọn ọkùnrin ó jẹ́ ọmọ-ogun ọdún tàbí bẹ́̀ lọ, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose."

Èyí ni àwọn ọmọ Israẹli ó jáde láti Ejibiti .

5 26.5-51: Nu 1.22-46. Àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́ọmọkùnrin Israẹli,

láti ẹni ti ìdílé Hanoku, láti ̀dọ̀ ẹni ìdílé Hanoku ti jáde ,

láti ìdílé Pallu, láti ̀dọ̀ ẹni ìdílé àwọn ọmọ Pallu ti jáde ;

6 ti Hesroni, ìdílé àwọn ọmọ Hesroni;

ti Karmi, ìdílé àwọn ọmọ Karmi.

7 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Reubeni; àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lẹ́gbẹ̀sán ó dín àádọ́rin (43,730).

8 Àwọn ọmọkùnrin Pallu ni Eliabu, 9 àwọn ọmọkùnrin Elifelehu ni Nemueli àti Eliabu, Datani àti Abiramu. Èyí ni Datani àti Abiramu náà wọ́n òkìkí nínú ìjọ ó jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ Mose àti Aaroni ó lára àwọn ẹgbẹ́ Kora nígbà wọ́n Olúwa . 10 Ilẹ̀ la ẹnu rẹ̀, ó gbé wọn pọ̀ pẹ̀Kora, nígbà ẹgbẹ́ rẹ̀ níbi iná ti run àwọn àádọ́ta nígba (250) ọkùnrin. wọ́n di àmì ìkìlọ̀. 11 Àwọn ọmọ Kora, ó ti ó , wọn .

12 Àwọn ọmọ ìran Simeoni ìdílé wọn:

ti Nemueli, ìdílé Nemueli;

ti Jamini, ìdílé Jamini;

ti Jakini, ìdílé Jakini;

13 ti Sera, ìdílé Sera;

Saulu, ìdílé Saulu.

14 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Simeoni, ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó igba (22,200) ọkùnrin.

15 Àwọn ọmọ Gadi ìdílé wọn:

ti Sefoni, ìdílé Sefoni;

ti Haggi, ìdílé Haggi;

ti Ṣuni, ìdílé Ṣuni;

16 ti Osni, ìdílé Osni;

ti Eri, ìdílé Eri;

17 ti Arodi, ìdílé Arodi;

ti Areli, ìdílé Areli.

18 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gadi iye wọn jẹ́ ̀kẹ́ méjì ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀ta (40,500).

19 Àwọn ọmọ Juda ni Eri àti Onani, ṣùgbọ́n Eri àti Onani ilẹ̀ Kenaani.

20 Àti àwọn ọmọ Juda gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Ṣela, ìdílé Ṣela;

ti Peresi, ìdílé Peresi;

ti Sera, ìdílé Sera.

21 Àwọn ọmọ Peresi:

ti Hesroni, ìdílé Hesroni;

ti Hamulu, ìdílé Hamulu.

22 Wọ̀nyí ni ìdílé Juda; gẹ́gẹ́ àwọn a nínú wọn iye wọn jẹ́ ẹgbàá méjìdínlógójì ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀ta (76,500).

23 Àwọn ọmọ Isakari gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Tola, ìdílé Tola;

ti Pufa, ìdílé Pufa;

24 ti Jaṣubu, ìdílé Jaṣubu;

ti Ṣimroni, ìdílé Ṣimroni.

25 Wọ̀nyí ni ìdílé Isakari gẹ́gẹ́ àwọn a nínú wọn iye wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó ̀́dúnrún (64,300).

26 Àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Seredi, ìdílé Seredi;

ti Eloni, ìdílé Eloni;

ti Jaleeli, ìdílé Jaleeli.

27 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ àwọn a nínú wọn iye wọn jẹ́ ̀kẹ́ mẹ́ta ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀ta (60,500).

28 Àwọn ọmọ Josẹfu gẹ́gẹ́ ìdílé wọn; Manase àti Efraimu.

29 Àwọn ọmọ Manase:

ti Makiri, ìdílé Makiri (Makiri Gileadi);

ti Gileadi, ìdílé àwọn ọmọ Gileadi.

30 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gileadi:

ti Ieseri, ìdílé Ieseri;

ti Heleki, ìdílé Heleki

31 àti ti Asrieli, ìdílé Asrieli;

àti ti Ṣekemu, ìdílé Ṣekemu;

32 àti Ṣemida, ìdílé àwọn ọmọ Ṣemida;

àti ti Heferi, ìdílé àwọn ọmọ Heferi.

33 (Selofehadi ọmọ Heferi ni ọmọkùnrin, ṣe ọmọbìnrin; orúkọ àwọn ọmọbìnrin ni Mahila, Noa, àti Hogla, Milka àti Tirsa).

34 Wọ̀nyí ni ìdílé Manase iye wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀rin (52,700).

35 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Efraimu gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

láti ̀dọ̀ Ṣutelahi, ìdílé àwọn ọmọ Ṣutelahi;

ti Bekeri, ìdílé àwọn ọmọ Bekeri;

ti Tahani, ìdílé àwọn ọmọ Tahani.

36 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ṣutelahi:

ti Erani, ìdílé àwọn ọmọ Erani.

37 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Efraimu, àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlógún ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀ta (32,500).

Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Josẹfu gẹ́gẹ́ ìdílé wọn.

38 Àwọn ọmọ Benjamini gẹ́gẹ́ ìdílé wọn nìyìí:

Bela, ìdílé àwọn ọmọ Bela;

ti Aṣbeli, ìdílé àwọn ọmọ Aṣbeli;

ti Ahiramu, ìdílé àwọn ọmọ Ahiramu;

39 ti Ṣufamu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣufamu;

ti Hufamu, ìdílé àwọn ọmọ Hufamu.

40 Àwọn ọmọ Bela ipasẹ̀ Ardi àti Naamani nìyìí:

ti Ardi, ìdílé àwọn ọmọ Ardi;

ti Naamani, ìdílé àwọn ọmọ Naamani.

41 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Benjamini; gẹ́gẹ́ ìdílé wọn; àti àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó ẹgbẹ̀jọ (45,600).

42 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dani gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Ṣuhamu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣuhamu.

Wọ̀nyí ni ìdílé Dani gẹ́gẹ́ ìdílé wọn. 43 Gbogbo ìdílé àwọn ọmọ Ṣuhamu, gẹ́gẹ́ àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó irinwó (64,400).

44 Ti àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Imina, ìdílé àwọn ọmọ Imina;

ti Iṣfi, ìdílé àwọn ọmọ Iṣfi;

ti Beriah, ìdílé àwọn ọmọ Berii.

45 Ti àwọn ọmọ Beriah:

ti Heberi, ìdílé àwọn ọmọ Heberi;

ti Malkieli, ìdílé àwọn ọmọ Malkieli.

46 (Orúkọ ọmọ Aṣeri obìnrin jẹ́ Sera.)

47 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó egbèje (53,400).

48 Ti àwọn ọmọ Naftali gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Jasieli, ìdílé àwọn ọmọ Jaseeli:

ti Guni, ìdílé àwọn ọmọ Guni;

49 ti Jeseri, ìdílé àwọn ọmọ Jeṣeri;

ti Ṣillemu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣillemu.

50 Wọ̀nyí ni ìdílé ti Naftali gẹ́gẹ́ ìdílé wọn, àwọn a nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó egbèje (45,400).

51 Àpapọ̀ iye a nínú àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ ọgbọ̀n ̀kẹ́ ó ẹgbẹ̀sán dín làádọ́rin (601,730).

52 Olúwa sọ fún Mose , 53 "Ilẹ̀ náà gbọdọ̀ jẹ́ pínpín fún wọn gẹ́gẹ́ ogún wọn gẹ́gẹ́ iye orúkọ wọn. 54 Fún àwọn ̀pọ̀ ni ìwọ ó fún ogún ìlú púpọ̀ àti fún àwọn ó kéré ni ìwọ ó fi kékeré fún, ẹnìkọ̀̀kan gbọdọ̀ gba ogún ìbí tirẹ̀ gẹ́gẹ́ ènìyàn a kọ. 55 dájú ilẹ̀ yìí gbọdọ̀ jẹ́ fífi ìbò pín gẹ́gẹ́ wọn ti pọ̀ . Gẹ́gẹ́ orúkọ ̀àwọn baba wọn ni wọn ó ni í. 56 Olúkúlùkù ogún ìní ni a gbọdọ̀ fi ìbò pín gẹ́gẹ́ wọ́n ti pọ̀ láàrín ńlá àti kékeré."

57 26.57-62: Nu 1.47-49. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Lefi a nínú wọn gẹ́gẹ́ ìdílé wọn:

ti Gerṣoni, ìdílé àwọn ọmọ Gerṣoni;

ti Kohati, ìdílé àwọn ọmọ Kohati;

ti Merari, ìdílé àwọn ọmọ Merari.

58 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Lefi;

ìdílé àwọn ọmọ Libni,

ìdílé àwọn ọmọ Hebroni,

ìdílé àwọn ọmọ Mahili,

ìdílé àwọn ọmọ Muṣi,

ìdílé àwọn ọmọ Kora.

(Kohati ni baba Amramu, 59 orúkọ aya Amramu ń jẹ́ Jokebedi, ọmọbìnrin Lefi, ìyá rẹ̀ fún Lefi Ejibiti. Òun Aaroni, Mose, àti Miriamu arábìnrin wọn fún Amramu. 60 Aaroni ni baba Nadabu àti Abihu, Eleasari àti Itamari. 61 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu , nígbà wọ́n ẹbọ níwájú Olúwa nígbà wọ́n iná àjèjì .)

62 Gbogbo àwọn ọmọkùnrin Lefi láti oṣù kan àti ju bẹ́̀ lọ ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lẹ́gbẹ̀rún (23,000). Wọn ka wọ́n mọ́ àwọn ọmọ Israẹli tókù nítorí wọ́n gba ogún ìní lára wọn.

63 Àwọn wọ̀nyí ni Mose àti Eleasari àlùfáà nígbà wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá odò Jordani létí Jeriko. 64 26.64,65: Nu 14.26-35.ẹnìkan nínú àwọn Mose àti Aaroni àlùfáà nígbà wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli aginjù Sinai. 65 Nítorí Olúwa ti sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kíkú ni wọn yóò aginjù, ẹnìkankan nínú wọn àfi Kalebu ọmọ Jefunne, àti Joṣua ọmọ Nuni.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também