Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 13

Ṣíṣe Ayọ́lẹ̀ilẹ̀ Kenaani

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Rán ènìyàn díẹ̀ láti lọ yẹ ilẹ̀ Kenaani èyí mo ti fún àwọn ọmọ Israẹli. Rán ẹnìkọ̀̀kan, ó jẹ́ olórí láti inú ̀kọ̀̀kan."

3 Mose rán wọn jáde láti aginjù Parani gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa. Gbogbo wọn jẹ́ olórí àwọn ènìyàn Israẹli.

4 Orúkọ wọn nìwọ̀nyí:

láti inú ̀Reubeni, Ṣammua ọmọ Sakkuri;

5 láti inú ̀Simeoni, Ṣafati ọmọ Hori;

6 láti inú ̀Juda, Kalebu ọmọ Jefunne;

7 láti inú ̀Isakari, Igali ọmọ Josẹfu;

8 láti inú ̀Efraimu, Hosea ọmọ Nuni;

9 láti inú ̀Benjamini, Palti ọmọ Rafu;

10 láti inú ̀Sebuluni, Daddieli ọmọ Sodi;

11 láti inú ̀Manase (̀Josẹfu), Gaddi ọmọ Susi;

12 láti inú ̀Dani, Ammieli ọmọ Gemalli;

13 láti inú ̀Aṣeri, Seturu ọmọ Mikaeli.

14 láti inú ̀Naftali, Nabi ọmọ Fofsi;

15 láti inú ̀Gadi, Geueli ọmọ Maki.

16 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ènìyàn Mose rán láti lọ yẹ ilẹ̀ náà . (Hosea ọmọ Nuni ni Mose sọ Joṣua.)

17 Nígbà Mose rán wọn lọ láti yẹ ilẹ̀ Kenaani , ó sọ fún wọn , "gba ̀gúúsù lọ títí àwọn ìlú olókè. 18 ó ilẹ̀ náà ti , bóyá àwọn ń gbé ilẹ̀ náà jẹ́ alágbára tàbí aláìlágbára, bóyá wọ́n pọ̀ tàbí wọn kéré. 19 Irú ilẹ̀ wo ni wọ́n gbé? Ṣé ilẹ̀ dára ni àbí èyí dára? Báwo ni ìlú wọn ti ? Ṣé ìlú olódi ni àbí èyí odi? 20 Báwo ni ilẹ̀ náà ti ? Ṣé ilẹ̀ ọlọ́ràá ni tàbí aṣálẹ̀? Ṣé igi níbẹ̀ àbí ? E sa ipá yín láti i díẹ̀ nínú èso ilẹ̀ náà ." (Ìgbà náà jẹ́ àkókò àkọ́pọ́n èso àjàrà gireepu.)

21 Bẹ́̀ ni wọ́n gòkè lọ láti yẹ ilẹ̀ náà , wọ́n lọ láti aginjù Sini títí Rehobu lọ́Lebo-Hamati. 22 Wọ́n gba gúúsù lọ Hebroni níbi Ahimani, Ṣeṣai àti Talmai í ṣe irú-ọmọ Anaki ń gbé. (A ti kọ́ Hebroni ọdún méje ṣáájú Ṣoani Ejibiti.) 23 Nígbà wọ́n àfonífojì Eṣkolu, wọ́n ̀ka kan ìdì èso àjàrà gireepu kan. Àwọn méjì fi ̀kan gbé e; wọ́n tún èso pomegiranate àti èso ̀pọ̀tọ́ pẹ̀. 24 Wọ́n sọ ibẹ̀ àfonífojì Eṣkolu nítorí ìdì èso gireepu àwọn ọmọ Israẹli níbẹ̀. 25 Wọ́n padà sílé lẹ́yìn ogójì ọjọ́ wọ́n ti lọ yẹ ilẹ̀ náà .

Ìròyìn nípa ilẹ̀ wọ́n yẹ̀

26 Wọ́n padà Mose àti Aaroni àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ijù Kadeṣi Parani. Wọ́n ìròyìn fún wọn àti fún gbogbo ìjọ ènìyàn, wọ́n fi èso ilẹ̀ náà hàn wọ́n. 27 Wọ́n fún Mose ìròyìn báyìí, "A lọ ilẹ̀ ibi o rán wa, lóòtítọ́ ń sàn fún wàrà àti fún oyin! Èso ibẹ̀ nìyìí. 28 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ń gbé níbẹ̀ lágbára, àwọn ìlú náà jẹ́ ìlú olódi bẹ́̀ ni ó tóbi púpọ̀. A tilẹ̀ àwọn irú-ọmọ Anaki níbẹ̀. 29 Àwọn Amaleki ń gbé ìhà gúúsù; àwọn ará Hiti, àwọn ará Jebusi àti àwọn ará Amori ni wọ́n ń gbé orí òkè ilẹ̀ náà, àwọn ará Kenaani ń gbé ̀òkun àti etí bèbè Jordani."

30 Kalebu pa àwọn ènìyàn náà lẹ́nu mọ́ níwájú Mose, ó , "jẹ́ á gòkè lọ lẹ́̀kan náà láti lọ gba ilẹ̀ náà, nítorí àwa le è gbà á."

31 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin wọ́n jọ gòkè lọ yẹ ilẹ̀ sọ , "Àwa le gòkè lọ àwọn ènìyàn wọ̀nyí nítorí wọ́n lágbára lọ." 32 Báyìí ni wọ́n ṣe ìròyìn búburú ti ilẹ̀ náà, wọ́n lọ yọ́fún àwọn ọmọ Israẹli. Wọ́n , "Ilẹ̀ a lọ yẹ̀ jẹ́ ilẹ̀ ń run àwọn olùgbé ibẹ̀. Gbogbo àwọn ènìyàn a níbẹ̀ jẹ́ ènìyàn fìrìgbọ̀n síngbọnlẹ̀. 33 13.33: Gẹ 6.4.A tún àwọn òmíràn (irú àwọn ọmọ Anaki) àwa i kòkòrò tata ojú ara wa, bẹ́̀ ni àwa náà ojú wọn."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também