Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 24

1 Nísinsin yìí nígbà Balaamu i ó tẹ́ Olúwa lọ́rùn láti bùkún àwọn Israẹli, lo ̀ìṣoṣó gẹ́gẹ́ ti ìgbà ìṣáájú, ṣùgbọ́n ó ojú rẹ̀ apá aginjù. 2 Nígbà Balaamu wo ìta ó Israẹli wọ́n pàgọ́ gẹ́gẹ́ ̀wọn, ̀Ọlọ́run sórí rẹ̀ 3 ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀,

"Àsọtẹ́lẹ̀ Balaamu ọmọ Beori,

àsọtẹ́lẹ̀ ẹni ojú rẹ̀ ríran kedere,

4 àsọtẹ́lẹ̀ ẹni ó gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run,

ẹni ó ríran láti ̀dọ̀ Olódùmarè,

ẹni ó dojúbolẹ̀, ojú rẹ̀ kedere.

5 "Àgọ́ rẹ ti dára , ìwọ Jakọbu,

àti ibùgbé rẹ, ìwọ Israẹli!

6 "Gẹ́gẹ́ àfonífojì ó tàn jáde,

gẹ́gẹ́ ọgbà ó ̀odò ńlá,

gẹ́gẹ́ igi aloe Olúwa gbìn,

gẹ́gẹ́ igi kedari ó lẹ́bàá odò.

7 Omi yóò sàn láti inú garawa:

èso wọn yóò ̀pọ̀lọpọ̀ omi.

"Ọba wọn yóò ga ju Agagi lọ;

ìjọba wọn yóò di gbígbéga.

8 "Ọlọ́run wọn jáde láti Ejibiti ;

wọ́n agbára gẹ́gẹ́ i ti àgbáǹréré.

Wọ́n jẹ orílẹ̀-èdè ń ṣe ̀rẹ̀ run,

wọ́n fọ́ egungun wọn túútúú;

wọ́n ó fi ọfà wọn ta wọ́n àtapòyọ.

9 24.9: Gẹ 49.9. Ó tẹríba ó dùbúlẹ̀ kìnnìún,

abo kìnnìún: ta ni ó gbọdọ̀ wọn?

"Ìbùkún ni fún ẹni ó bùkún fún ,

ìfibú jẹ́ ti ẹni ó fi ́ !"

10 Nígbà náà ni ìbínú Balaki Balaamu. Ó fi ọwọ́ lu ọwọ́ ó , "Mo ́ láti àwọn ̀mi ṣùgbọ́n o tún bùkún fún wọn nígbà mẹ́ta yìí. 11 Nísinsin yìí sálọ ibùjókòó rẹ! Èmi ti láti sọ ́ di ẹni ńlá, ṣùgbọ́n Olúwa ́ sẹ́yìn láti gba èrè yìí."

12 Balaamu Balaki lóhùn, "Ǹjẹ́ èmi sọ fún àwọn ìránṣẹ́ o rán mi , 13 Kódà Balaki fún mi ààfin rẹ̀ ó kún fún fàdákà àti wúrà, èmi le ṣe ohunkóhun lọ́wọ́ ara mi, yálà búburú tàbí rere, láti kọjá òfin Olúwa: ohun Olúwa ni èmi ó sọ? 14 Nísinsin yìí ń padà lọ ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi, ṣùgbọ́n jẹ́ èmi ó kìlọ̀ fún nítorí nǹkan àwọn ènìyàn wọ̀nyí yóò ṣe àwọn ènìyàn rẹ ọjọ́ iwájú."

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ ̀kẹrin Balaamu

15 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe:

"Òwe Balaamu ọmọ Beori,

òwe ẹni ojú rẹ̀ ríran kedere,

16 ẹni gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run ń ,

ó mọ ìmọ̀ ̀gá-ògo,

ó ríran láti ̀dọ̀ Olódùmarè,

ẹni ó dọ̀bálẹ̀, ojú rẹ̀ ṣí:

17 "Mo i, ṣùgbọ́n í ṣe ìsinsin yìí.

Mo kíyèsi, ṣùgbọ́n súnmọ́.

Ìràwọ̀ kan yóò jáde láti ̀dọ̀ Jakọbu;

yóò yọ jáde láti Israẹli.

Yóò tẹ̀ fọ́ orí Moabu,

yóò fọ́ agbárí gbogbo ọmọ Seti.

18 Wọn yóò borí Edomu;

yóò ṣẹ́gun Seiri ̀rẹ̀,

ṣùgbọ́n Israẹli yóò dàgbà nínú agbára.

19 Olórí yóò jáde láti Jakọbu

yóò pa àwọn ṣẹ́nínú ìlú náà run."

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ ìkẹyìn Balaamu

20 Nígbà náà ni Balaamu Amaleki ó bẹ̀rẹ̀ òwe:

"Amaleki ni àkọ́kọ́ nínú àwọn orílẹ̀-èdè,

ṣùgbọ́n yóò dahoro níkẹyìn."

21 Nígbà náà ó ará Keni ó bẹ̀rẹ̀ òwe:

"Ibùgbé rẹ ààbò,

ìtẹ́ rẹ ni a sínú àpáta;

22 síbẹ̀ ̀yin ará Keni ni yóò di píparun

nígbà Asiria yín ìgbèkùn."

23 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe rẹ̀:

"Háà, ta ni ó nígbà Ọlọ́run ṣe èyí?

24 Ọkọ̀ yóò láti ibùdókọ̀ Kittimu;

wọn yóò ṣẹ́gun Asiria àti Eberi,

ṣùgbọ́n àwọn náà yóò di píparun."

25 Nígbà náà ni Balaamu dìde ó padà ilé rẹ̀, Balaki lọ ̀tirẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também