Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 2

Ìrìn àrè aginjù

1 2.1-8: Nu 21.4-20. Nígbà náà ni a yípadà, a ̀wa pọ̀n lọ aginjù, a gba ̀Òkun Pupa, Olúwa ti darí mi. Ìgbà pípẹ́ ni a fi ń rìn kiri yíká agbègbè àwọn ìlú olókè Seiri.

2 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi , 3 "ti rìn agbègbè ilẹ̀ olókè yìí pẹ́ , nísinsin yìí, yípadà ìhà àríwá. 4 2.4: Gẹ 36.8.Fún àwọn ènìyàn náà àwọn òfin wọ̀nyí: ti fẹ́ la ilẹ̀ àwọn arákùnrin yín kọjá, àwọn ọmọ Esau; àwọn ará Edomu ń gbé Seiri. ̀yín yóò wọ́n, ṣùgbọ́n ṣọ́ra gidigidi. 5 ṣe wọn níjà torí èmi fún un yín èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn. ó ti ó kéré mọ èmi fún un yín. Mo ti fi ilẹ̀ òkè Seiri fún Esau gẹ́gẹ́ ìní rẹ̀. 6 san owó oúnjẹ jẹ fún wọn àti omi mu.’ "

7 Olúwa Ọlọ́run yín ti bùkún un yín nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín. Ó ti mójútó ìrìnàjò yín nínú aginjù ńlá yìí. Olúwa Ọlọ́run yín pẹ̀u yín ogójì ọdún wọ̀nyí, bi ̀yin ṣaláìní ohunkóhun.

8 Bẹ́̀ ni a kọjá ̀dọ̀ àwọn arákùnrin wa, àwọn ọmọ Esau ń gbé Seiri. A kúrò ̀Arabah èyí ó láti Elati àti Esioni-Geberi, a rìn gba ̀aginjù Moabu.

9 Olúwa sọ fún mi , "ṣe dẹ́rùba àwọn ará Moabu bẹ́̀ ni ṣe wọn jagun torí n fi èyíkéyìí nínú ilẹ̀ wọn fún un yín. Mo ti fi Ari fún àwọn ọmọ Lọti i ìní."

10 (Àwọn Emimu ti gbé ibẹ̀ , àwọn ènìyàn síngbọnlẹ̀ pọ̀, wọ́n ga àwọn Anaki. 11 Gẹ́gẹ́ Anaki àwọn ènìyàn náà wọ́n ará Refaimu ṣùgbọ́n àwọn ará Moabu wọ́n Emimu. 12 Àwọn ará Hori gbé Seiri, àwọn ọmọ Esau wọn kúrò níwájú wọn. Wọ́n gba ilẹ̀ wọn, wọ́n tẹ̀ààyè wọn gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ Israẹli ṣe ilẹ̀ Olúwa yóò fún wọn ìní wọn.)

13 Olúwa , "dìde, la àfonífojì Seredi kọjá." Bẹ́̀ ni a la àfonífojì náà kọjá.

14 2.14: Nu 14.28-35. Ó gbà ọdún méjìdínlógójì ó di a la àfonífojì Seredi kọjá láti ìgbà a ti kúrò Kadeṣi-Barnea. Nígbà náà gbogbo ìran àwọn ó jẹ́ jagunjagun láàrín àwọn ènìyàn náà ti ṣègbé kúrò láàrín àwọn ènìyàn náà àsìkò yìí Olúwa ti búra fún wọn. 15 Ọwọ́ Olúwa lòdì wọn nítòótọ́, láti run wọn kúrò nínú ibùdó, títí gbogbo wọn fi run tan.

16 Lẹ́yìn ẹni ó gbẹ̀yìn pátápátá nínú àwọn jagunjagun àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti , 17 Olúwa sọ fún mi , 18 "Lónìí ni ̀yin yóò la agbègbè Moabu kọjá Ari. 19 ̀dọ̀ àwọn ará Ammoni, ṣe halẹ̀ mọ́ wọn, gbọdọ̀ wọn jagun, torí èmi yóò fi àwọn ilẹ̀ ó jẹ́ ti àwọn ará Ammoni fún un yín ìní. Mo ti fi fún àwọn ọmọ Lọti ìní."

20 (A ka ilẹ̀ yìí ilẹ̀ àwọn Refaimu, wọ́n ti gbé níbẹ̀ , ṣùgbọ́n àwọn ará Ammoni ń wọ́n ará Samsummimu. 21 Wọ́n jẹ́ àwọn ènìyàn lágbára, wọ́n pọ̀, wọ́n ga gogoro àwọn ará Anaki. Olúwa run wọn kúrò níwájú àwọn ará Ammoni, wọ́n wọn jáde wọ́n gba ilẹ̀ wọn. 22 Bákan náà ni Olúwa ṣe fún àwọn ọmọ Esau, wọ́n ń gbé Seiri, nígbà ó pa àwọn ará Hori run níwájú wọn. Wọ́n wọn jáde wọ́n ń gbé ilẹ̀ wọn títí di òní. 23 Nípa ti àwọn ará Affimu, wọ́n ń gbé àwọn ìlú kéékèèké Gasa, àwọn ará Kaftorimu, wọ́n jáde láti Krete ni ó pa wọ́n run, wọ́n gba ilẹ̀ wọn.)

Israẹli ṣẹ́gun Sioni ọba Heṣboni

24 "gbáradì, kọjá odò Arnoni. Kíyèsi, Mo ti fi Sihoni ará Amori, ọba Heṣboni àti ilẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́. ilẹ̀ náà jagun gbà á. 25 Èmi bẹ̀rẹ̀ fi ìbẹ̀àti ìfòyà yín sára gbogbo orílẹ̀-èdè lábẹ́ ̀run láti òní lọ. Wọn yóò gbọ́ ìròyìn in yín, wọn yóò wárìrì, wọn yóò nínú ìdààmú ọkàn torí i tiyín."

26 Mo rán àwọn ìránṣẹ́ láti aginjù Kedemoti lọ́ sọ́dọ̀ Sihoni ọba Heṣboni pẹ̀̀rọ̀ àlàáfíà , 27 "Jẹ́ a la ilẹ̀ yín kọjá. Àwa yóò gba ti òpópónà nìkan. A sọ́tùn tàbí sósì. 28 ta oúnjẹ a ó jẹ àti omi a ó mu fún wa iye owó wọn. Kìkì à jẹ́ a rìn kọjá: 29 gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ Esau ó ń gbé Seiri àti àwọn ará Moabu ó ń gbé Ari, ti gbà láààyè títí a fi la Jordani ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa yóò fún wa." 30 Ṣùgbọ́n Sihoni ọba Heṣboni gbà fún wa láti kọjá. Torí Olúwa Ọlọ́run yín ti ọkàn rẹ̀ yigbì, àyà rẹ̀ kún fún agídí ó ba à le fi e yín lọ́wọ́, ó ti ṣe báyìí.

31 Olúwa mi sọ̀rọ̀ , "Kíyèsi i, mo ti bẹ̀rẹ̀ fi Sihoni àti ilẹ̀ rẹ̀ e yín lọ́wọ́. Báyìí, máa ṣẹ́gun rẹ̀, gba ilẹ̀ rẹ̀."

32 Nígbà Sihoni àti gbogbo àwọn jagunjagun rẹ̀ jáde láti wa jagun Jahasi, 33 Olúwa Ọlọ́run wa fi wa lọ́wọ́ bẹ́̀ ni a ṣẹ́gun rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo ológun rẹ̀. 34 Nígbà náà, gbogbo ìlú wọn ni a a pa wọ́n run pátápátá tọkùnrin, tobìnrin àti gbogbo ọmọ wọn. A ẹnikẹ́ni . 35 Ṣùgbọ́n a gbogbo ohun ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú a ṣẹ́gun fún ara wa. 36 Láti Aroeri, létí odò Arnoni àti láti àwọn ìlú ó lẹ́bàá odò náà títí ó fi Gileadi, ìlú ó lágbára fún wa, Olúwa Ọlọ́run wa fi gbogbo wọn fún wa. 37 ìbámu pẹ̀òfin Olúwa Ọlọ́run wa, súnmọ́ ̀kan nínú ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, bẹ́̀ ni ilẹ̀ ó lọ Jabbok, tàbí ilẹ̀ ó àwọn ìlú òkè e .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também