Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 16

Àjọ ìrékọjá

1 16.1-17: El 23.14-17; Le 23; Nu 28–29. kíyèsi oṣù Abibu, máa ṣe àjọ̀dún ìrékọjá ti Olúwa Ọlọ́run yín, nítorí oṣù Abibu yìí ni ó un yín jáde Ejibiti lóru. 2 fi ẹran kan ẹbọ ìrékọjá Olúwa Ọlọ́run yín láti inú ̀wọ́ ẹran tàbí agbo màlúù yín ibi Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn ibùgbé fún orúkọ rẹ̀. 3 ṣe jẹ ́ pẹ̀u àkàrà a fi ìwúkàrà ṣe, ṣùgbọ́n ọjọ́ méje ni fi jẹ àkàrà ìwúkàrà, àkàrà ìpọ́njú, nítorí pẹ̀ìkánjú ni kúrò Ejibiti: à rántí ìgbà kúrò Ejibiti gbogbo ọjọ́ ayé yín. 4 a ṣe àkàrà wíwú ̀dọ̀ rẹ nínú ilẹ̀ rẹ ijọ́ méje. ìwọ ṣe jẹ́ nǹkan kan ṣẹ́nínú ẹran ìwọ ó fi ẹbọ ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kìn-ín-ní di àárọ̀ ọjọ́ kejì.

5 gbọdọ̀ ṣe ìrékọjá náà ìlúkílùú kankan, Olúwa Ọlọ́run yín fi fún un yín 6 ṣe ibi yóò yàn gẹ́gẹ́ ibùgbé fún orúkọ rẹ̀, níbẹ̀ ni ki ti ṣe ìrúbọ ìrékọjá náà ìrọ̀lẹ́ nígbà oòrùn ń wọ̀ gẹ́gẹ́ ìrántí ìgbà kúrò ilẹ̀ Ejibiti. 7 sun ún jẹ ́ ibi Olúwa Ọlọ́run yín yóò yàn. àárọ̀, padà àgọ́ yín. 8 Ọjọ́ mẹ́fi jẹ àkàrà aláìwú, ọjọ́ keje, pe àjọ kan fún Olúwa Ọlọ́run yín, ṣe iṣẹ́ kankan.

Ayẹyẹ àwọn ̀sẹ̀

9 Ka ̀sẹ̀ méje láti ìgbà ti bẹ̀rẹ̀ fi dòjé ṣe ìkórè ọkà. 10 Nígbà náà ni ṣe àjọ ̀sẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín, nípa pípèsè ọrẹ àtinúwá, gẹ́gẹ́ ìbùkún Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín. 11 máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín ibi yóò yàn ibùgbé fún orúkọ rẹ̀: ̀yin, àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin, àwọn ẹrú yín ọkùnrin àti àwọn ẹrú yín obìnrin, àwọn Lefi ó ìlú yín, àti àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba, àti àwọn opó ń gbé àárín yín. 12 rántí , ti jẹ́ ẹrú Ejibiti , nítorí náà tẹ̀àwọn ìlànà wọ̀nyí dáradára.

Ayẹyẹ àgọ́ ìpàdé

13 ṣe ayẹyẹ àgọ́ ìpàdé fún ọjọ́ méje lẹ́yìn ìgbà ti kórè oko yín ti pakà ti fún ọtí tán. 14 máa yọ̀ àkókò àjọ̀dún un yín, ̀yin, àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti obìnrin, àwọn ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin yín, àti àwọn Lefi, àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba àti àwọn opó ń gbé àwọn ìlú u yín. 15 Ọjọ́ méje ni ̀yin ó fi ṣe ayẹyẹ fún Olúwa Ọlọ́run yín ibi Olúwa yóò yàn. Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín yóò bùkún un yín gbogbo ìkórè e yín, àti gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín, ayọ̀ yín yóò kún.

16 ̀̀mẹ́ta lọ́dún ni gbogbo àwọn ọkùnrin rẹ ó farahàn níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ibi yóò yàn. Níbi àjọ àkàrà àìwú, níbi àjọ ̀sẹ̀, àti àjọ àgọ́ ìpàdé. Ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ iwájú Olúwa ọwọ́ òfo. 17 olúkúlùkù ó ọrẹ agbára rẹ̀ ti , gẹ́gẹ́ ìbùkún Olúwa Ọlọ́run rẹ ó fi fún un ̀.

Àwọn adájọ́

18 yan àwọn adájọ́ àti àwọn olóyè fún ̀a yín kọ̀̀kan, gbogbo ìlú Olúwa Ọlọ́run yín yóò fún un yín, wọ́n gbọdọ̀ máa fi òtítọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn. 19 16.19: El 23.6-9; Le 19.15.Ìwọ gbọdọ̀ ìdájọ́ po, ìwọ gbọdọ̀ ṣe ojúsàájú ènìyàn. Ìwọ gbọdọ̀ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ń fọ́ ojú ọlọ́gbọ́n, ó ń ba ̀rọ̀ olódodo jẹ́. 20 tẹ̀ìdájọ́ òtítọ́ àní ìdájọ́ òtítọ́ nìkan, à gbé gba ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín ń fún un yín.

sin ọlọ́run mìíràn

21 16.21,22: Le 26.1. ṣe ri ère òrìṣà Aṣerah ̀gbẹ́ pẹpẹ ti mọ fún Olúwa Ọlọ́run yín. 22 gbọdọ̀ gbé òkúta òrìṣà gbígbẹ́ kan kalẹ̀ fún ara yín, nítorí èyí ni Olúwa Ọlọ́run yín kórìíra.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também