Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 29

Ìsọdi tuntun májẹ̀

1 Èyí ni àwọn ìpinnu májẹ̀Olúwa pàṣẹ fún Mose láti ṣe pẹ̀àwọn ọmọ Israẹli Moabu, àfikún májẹ̀ó ti ṣe pẹ̀u wọn Horebu.

2 Mose pàṣẹ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó fún wọn ,

ojú rẹ ti gbogbo ohun Olúwa ti ṣe Ejibiti Farao àti, gbogbo àwọn ìjòyè e rẹ̀ àti ilẹ̀ rẹ̀. 3 Pẹ̀ojú ara rẹ ni ìwọ àwọn ìdánwò ńlá náà, àwọn iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá. 4 29.4: Ro 11.8.Ṣùgbọ́n títí di àsìkò yìí Olúwa fi ọkàn ìmòye tàbí ojú ó ń tàbí etí ó n gbọ́ fún . 5 Nígbà ogójì ọdún ń tọ́ yín ṣọ́aginjù, aṣọ ̀ rẹ gbó tàbí bàtà ẹsẹ̀ rẹ. 6 O jẹ oúnjẹ tàbí mu wáìnì kankan tàbí ohun mímu mìíràn. Mo ṣe èyí o mọ̀ Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ.

7 Nígbà o ibí yìí, Sihoni ọba Heṣboni àti Ogu ọba Baṣani jáde láti , ṣùgbọ́n a ṣẹ́gun wọn. 8 A gba ilẹ̀ wọn a fi fún àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ̀Manase ogún.

9 Nítorí náà, pa májẹ̀yìí mọ́, máa ṣe wọ́n, ̀yin ó máa ire nínú gbogbo ohun o ń ṣe. 10 Gbogbo yín ń dúró lónìí yìí níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ: àwọn olórí yín, àwọn ̀yín, àwọn àgbàgbà yín àti àwọn ìjòyè yín, àní gbogbo àwọn ọkùnrin mìíràn Israẹli, 11 pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ ̀ rẹ àti ìyàwó ò rẹ àti àwọn àjèjì wọ́n ń gbé àgọ́ ̀ rẹ, ó pópòpó igi rẹ, ó gbé omi rẹ. 12 O dúró níhìn-ín yìí o wọ inú májẹ̀pẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ, májẹ̀Olúwa ń ṣe pẹ̀rẹ lónìí yìí àti òun pẹ̀ìbúra, 13 láti jẹ́wọ́ rẹ lónìí yìí ènìyàn an rẹ̀, ó jẹ́ Ọlọ́run rẹ ó ti ṣèlérí àti ó ti ṣe ìbúra fún àwọn baba à rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu. 14 Èmi ń ṣe májẹ̀yìí, pẹ̀ìbúra rẹ̀, í ṣe fún ìwọ nìkan 15 ó dúró níbí pẹ̀wa lónìí níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ṣùgbọ́n àti fún gbogbo àwọn níbí lónìí.

16 Ìwọ fúnra à rẹ mọ a ṣe gbé Ejibiti àti a ṣe kọjá láàrín àwọn orílẹ̀-èdè nílẹ̀ ibí yìí. 17 Ìwọ láàrín wọn ìríra wọn, àwọn ère àti àwọn òrìṣà igi àti ti òkúta, ti fàdákà àti ti wúrà. 18 29.18: Ap 8.23; Hb 12.15.i dájú ọkùnrin tàbí obìnrin, ìdílé tàbí ̀láàrín yín lónìí ọkàn an rẹ̀ yóò kúrò lọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa láti lọ àti láti sin àwọn ọlọ́run àwọn orílẹ̀-èdè náà; i dájú gbòǹgbò ó ń irú èso kíkan bẹ́̀ jáde láàrín yín.

19 Nígbà irú ẹni bẹ́̀ gbọ́ ìbúra yìí, ó gbàdúrà ìbùkún sórí ara rẹ̀ nígbà náà ni ó ronú, "Èmi yóò àlàáfíà, ó tilẹ̀ jẹ́ mo ti fi àáké kọ́nípa lílọ nínú ̀ti ara à mi." Èyí yóò àjálù sórí ilẹ̀ tútù àti sórí ilẹ̀ gbígbẹ bákan náà 20 Olúwa yóò ìfẹ́ àti dáríjì í; ìbínú àti ìtara rẹ̀ yóò ọkùnrin náà. Gbogbo àwọn ègún a kọ sínú ìwé yìí yóò sórí i rẹ̀, Olúwa yóò yọ orúkọ rẹ̀ kúrò lábẹ́ ̀run. 21 Olúwa yóò yọ òun nìkan kúrò nínú gbogbo ̀Israẹli fún àjálù, gẹ́gẹ́ gbogbo ègún májẹ̀a kọ inú ìwé òfin yìí.

22 Àwọn ọmọ rẹ ó tẹ̀ìran rẹ lẹ́yìn àti àwọn àjèjì ó láti ilẹ̀ jíjìn yóò wàhálà ó sórí ilẹ̀ àti àwọn ààrùn pẹ̀Olúwa . 23 Gbogbo ilẹ̀ náà yóò di imí-oòrùn, àti iyọ̀, àti ìjóná a fi ọkàn , tàbí so èso tàbí koríko nínú u rẹ̀, yóò dàbí ìbìṣubú Sodomu àti Gomorra, Adma àti Seboimu, Olúwa ṣubú nínú ìbínú rẹ̀, àti ìkáàánú rẹ̀. 24 Gbogbo orílẹ̀-èdè yóò béèrè , "Olúwa fi ṣe èyí ilẹ̀ yìí? ni a mọ ooru ìbínú ńlá yìí ?"

25 Ìdáhùn yóò jẹ́ báyìí: "Nítorí ènìyàn yìí kọ Olúwa Ọlọ́run baba wọn sílẹ̀, májẹ̀ó ti wọn nígbà ó wọn jáde láti Ejibiti. 26 Wọ́n lọ wọ́n sin ọlọ́run mìíràn, wọ́n foríbalẹ̀ fún wọn, ọlọ́run wọn mọ̀, ọlọ́run fi fún wọn. 27 Nígbà náà ni ìbínú Olúwa ru ilẹ̀ wọn, bi ó gbogbo ègún a kọ sínú ìwé yìí sórí i rẹ̀. 28 ìbínú àti ìkáàánú, àti ìrunú ńlá, Olúwa wọ́n tu kúrò ilẹ̀ wọn, ó wọn lọ ilẹ̀ mìíràn, ó ti òní yìí."

29 Ohun ìkọ̀kọ̀ jẹ́ ti Olúwa Ọlọ́run wa, ṣùgbọ́n ohun a fihàn jẹ́ ti wa àti ti àwọn ọmọ wa títí láé, a tẹ̀gbogbo ̀rọ̀ inú òfin yìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também