Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 9

í ṣe nítorí òdodo Israẹli

1 Gbọ́, ìwọ Israẹli. Báyìí, ̀yin ti gbáradì láti la Jordani kọjá, láti lọ gba ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n tóbi, wọ́n lágbára yín lọ, wọ́n àwọn ìlú ńlá ńlá, odi wọn kan ̀run. 2 Àwọn ènìyàn náà lágbára wọ́n ga àní àwọn ọmọ Anaki ni wọ́n. gbọ́ nípa wọn, gbọ́ àwọn ènìyàn ń sọ nípa wọn , "Ta ni ó le è dojú ìjà kọ àwọn ọmọ Anaki (òmíràn)?" 3 9.3: Hb 12.29.Ṣùgbọ́n ó a yín lójú lónìí Olúwa Ọlọ́run yín ni ó ń ṣáájú u yín lọ gẹ́gẹ́ iná ajónirun. Yóò wọn run, yóò tẹ orí wọn ba níwájú yín. ̀yin yóò wọ́n jáde, ̀yin yóò run wọ́n kíákíá, Olúwa ti ṣèlérí fún un yín.

4 Lẹ́yìn Olúwa Ọlọ́run yín ti wọn jáde níwájú u yín, ṣe fún ara yín , "Torí òdodo mi Olúwa ṣe mi síbí láti gba ilẹ̀ náà." Rárá, ṣùgbọ́n nítorí ìwà búburú àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ni Olúwa yóò ṣe wọn jáde níwájú u yín. 5 í ṣe nítorí òdodo yín, tàbí ìdúró ṣinṣin ni ó fi wọ ìlú wọn lọ láti gba ilẹ̀ wọn, ṣùgbọ́n nítorí ìwà búburú àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ni Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi wọn jáde kúrò níwájú u yín láti ohun ó búra fún àwọn baba ṣẹ: fún Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu. 6 Ṣùgbọ́n ó yín í ṣe nítorí òdodo yín ni Olúwa Ọlọ́run yín fi ń fún un yín ilẹ̀ rere náà, láti , nítorí ènìyàn ọlọ́rùn líle ni jẹ́.

Ère òrìṣà wúrà

7 rántí, ṣe gbàgbé ̀yin ti Olúwa Ọlọ́run yín bínú aginjù. Láti ọjọ́ ti kúrò Ejibiti ni ̀yin ti ń ṣọ̀tẹ̀ Olúwa títí ̀yin fi ìhín yìí. 8 9.8-21: El 32.7-20.Horebu ̀yin ti Olúwa bínú, títí bi ó fẹ́ run yín. 9 Nígbà mo gòkè lọ láti lọ gba wàláà òkúta, wàláà májẹ̀ti Olúwa ti a yín . Ogójì ̀sán àti òru ni mo fi lórí òkè náà, èmi fẹnu kan oúnjẹ bẹ́̀ ni ń mu omi. 10 Olúwa fún mi wàláà òkúta méjì a fi ìka Ọlọ́run kọ. Lórí wọn ni a kọ àwọn òfin Ọlọ́run sọ fún un yín lórí òkè láàrín iná, ọjọ́ ìpéjọpọ̀ .

11 Lópin ogójì ̀sán àti òru wọ̀nyí, Olúwa fún mi sílétì òkúta méjì, wàláà òkúta májẹ̀náà. 12 Bẹ́̀ ni Olúwa sọ fún mi , "Sọ̀kalẹ̀ kúrò níhìn-ín kíákíá, torí àwọn ènìyàn rẹ o jáde láti Ejibiti ti hùwà ìbàjẹ́. Wọ́n ti yípadà kúrò, nínú ̀mi, wọ́n ti ṣe ère dídá fún ara wọn."

13 Olúwa sọ fún mi , "Mo ti àwọn ènìyàn wọ̀nyí ènìyàn ọlọ́rùn líle gbá à ni wọ́n. 14 Fi sílẹ̀, jẹ́ n run wọ́n, n pa orúkọ wọn rẹ́ kúrò lábẹ́ ̀run. Èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ó lágbára ó pọ̀wọ́n lọ."

15 Báyìí ni mo yípadà, sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà , orí òkè o ń yọ iná. Àwọn wàláà májẹ̀méjèèjì lọ́wọ́ mi. 16 Ìgbà mo ṣàkíyèsí, mo i ti dẹ́ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín. ti ṣe ère òrìṣà ìrí ̀dọ́ màlúù, fún ara yín. ti yípadà kánkán kúrò nínú ̀Olúwa ti pàṣẹ fún un yín. 17 Bẹ́̀ ni ju wàláà méjèèjì náà mọ́lẹ̀, mo fọ́ wọn wẹ́wẹ́ lójú u yín.

18 Lẹ́yìn náà mo tún wólẹ̀ níwájú Olúwa fún ogójì ̀sán àti ogójì òru, èmi jẹ oúnjẹ kankan bẹ́̀ ni èmi mu omi, nítorí gbogbo ̀ṣẹ̀ , ń ṣe búburú lójú Olúwa, ń u bínú. 19 Mo bẹ̀ìbínú àti ìrunú Olúwa, nítorí inú i i yín bi ó fẹ́ pa yín run. Ṣùgbọ́n Olúwa tún fetí mi lẹ́̀kan i. 20 Inú Olúwa Aaroni láti pa á run, nígbà náà ni mo tún gbàdúrà fún Aaroni náà. 21 Bẹ́̀ ni mo ohun ó un yín dẹ́ṣẹ̀, àní ère ẹgbọrọ màlúù ti ṣe, mo fi iná sun ún, bẹ́̀ ni mo gún un, mo lọ̀ ́ lúúlúú eruku lẹ́búlẹ́, mo da ̀lọ̀ rẹ̀ sínú odò ń sàn nísàlẹ̀ òkè.

22 ̀yin tún Olúwa bínú Tabera, Massa àti Kibirotu-Hattaafa.

23 Nígbà Olúwa ran an yín jáde Kadeṣi-Barnea, Ó , "gòkè lọ, gba ilẹ̀ náà mo fi fún un yín." Ṣùgbọ́n ṣọ̀tẹ̀ òfin Olúwa Ọlọ́run yín. gbẹ́kẹ̀e, bẹ́̀ ni gbọ́ tirẹ̀. 24 Láti ìgbà mo ti mọ̀ yín ni ti ń ṣọ̀tẹ̀ Olúwa.

25 Mo ti wólẹ̀ níwájú Olúwa fún ogójì ̀sán àti òru wọ̀nyí nítorí Olúwa sọ Òun yóò pa yín run. 26 Mo gbàdúrà Olúwa , "Olúwa Olódùmarè, ṣe run àwọn ènìyàn rẹ, àní ogún rẹ o ti padà, nípa agbára rẹ o fi agbára ńlá wọn jáde láti Ejibiti . 27 Rántí àwọn ìránṣẹ́ rẹ Abrahamu, Isaaki, àti Jakọbu. Fojú fo orí kunkun àwọn ènìyàn yìí, pẹ̀ìwà búburú àti ̀ṣẹ̀ wọn. 28 bẹ́̀ kọ́, orílẹ̀-èdè ìwọ ti wa jáde yóò , Torí Olúwa wọn lọ ilẹ̀ náà ó ti ṣèlérí fún wọn, àti ó ti kórìíra wọn, ni ó fi wọn jáde láti pa wọ́n aginjù.29 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn rẹ ni wọ́n, ogún rẹ o ti fi ọwọ́ agbára rẹ àti nínà ọwọ́ rẹ jáde."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também