Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 18

Ọrẹ fún àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi

1 18.1-8: Nu 18.20-24. Àwọn àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi, àní gbogbo ̀Lefi, wọn yóò ìpín tàbí ogún láàrín Israẹli, wọn yóò máa jẹ nínú ọrẹ ẹbọ a fi iná ṣe Olúwa, nítorí òun ni ogún un tiwọn. 2 Wọn yóò ìní láàrín àwọn arákùnrin wọn; Olúwa ni yóò jẹ́ ìní i tiwọn, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe ìlérí fún wọn.

3 Gbogbo èyí ni yóò jẹ́ ìpín àwọn àlùfáà láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ó fi akọ màlúù tàbí àgùntàn ẹbọ; wọn yóò fi èjìká àti ̀rẹ̀kẹ́ méjèèjì àti gbogbo inú fún àlùfáà. 4 Àkọ́so irúgbìn ọkà rẹ, ti wáìnì àti ti òróró rẹ, àti àkọ́rẹ́ irun àgùntàn rẹ ni ìwọ yóò fi fún wọn. 5 Nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti yàn wọ́n àti àwọn ọmọ wọn láti inú gbogbo ̀láti dúró àti láti ṣe ìránṣẹ́ orúkọ Olúwa títí láé.

6 ọmọ Lefi kan láti ibikíbi nínú àwọn ìlú u yín Israẹli, níbi ó ń gbé ṣe àtìpó, ó gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀ ibi Olúwa yóò yàn. 7 Nígbà náà ni ó máa ṣe ìránṣẹ́ orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ Lefi arákùnrin rẹ̀ ti ń dúró ṣe iṣẹ́ ìsìn níwájú Olúwa níbẹ̀. 8 Wọn yóò ìpín kan láti jẹ, ó tilẹ̀ jẹ́ ó ti gba owó nípa títa ogún baba rẹ̀.

Ohun ìríra

9 Nígbà o wọ ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò fi fún , ìwọ gbọdọ̀ kọ́ láti tẹ̀àwọn ̀ìríra àwọn orílẹ̀-èdè náà ó níbẹ̀. 10 18.10,11: Ek 22.18; Le 19.26,31; 20.6,27.ṣe jẹ́ a ẹnikẹ́ni láàrín yín ó fi ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tàbí ọmọ rẹ̀ obìnrin la iná (fi ọmọ rẹ ẹbọ) ẹnikẹ́ni ṣe lọ fọ àfọ̀ṣẹ, tàbí ṣẹ́ oṣó, tàbí túmọ̀ àwọn àmì nǹkan ń bọ̀, tàbí àjẹ́, 11 tàbí afògèdè, tàbí jẹ́ a iwin gbìmọ̀ tàbí oṣó tàbí abókùúsọ̀rọ̀. 12 Ẹnikẹ́ni ṣe nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ìríra Olúwa, àti nítorí àwọn ìwà ìríra wọ̀nyí ni Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò fi àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jáde kúrò níwájú rẹ. 13 18.13: Mt 5.48.O láti jẹ́ aláìlẹ́gàn níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ.

Wòlíì

14 Àwọn orílẹ̀-èdè ìwọ yóò gba ilẹ̀ wọ́n ń gbé, wọ́n fetí àwọn ó ń ṣe oṣó tàbí ṣe àfọ̀ṣẹ. Ṣùgbọ́n, ti ìwọ, Olúwa Ọlọ́run rẹ fi ààyè gbà ́ láti ṣe bẹ́̀. 15 18.15-19: Ap 3.22,23; 7.37.Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbé wòlíì kan dìde gẹ́gẹ́ èmi láàrín àwọn arákùnrin rẹ. Tìrẹ ni o gbọ́. 16 Nítorí èyí ni ohun ìwọ béèrè lọ́wọ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ Horebu ọjọ́ àjọ, nígbà ìwọ , "àwa ṣe gbọ́ ohùn Olúwa Ọlọ́run wa tàbí iná ńlá yìí mọ́. bẹ́̀ kọ́ àwa yóò ."

17 Olúwa fún mi , "Ohun wọ́n sọ dára. 18 Èmi yóò gbé wòlíì kan dìde fún wọn láàrín àwọn arákùnrin wọn ìwọ, Èmi yóò fi ̀rọ̀ mi i ẹnu, yóò sọ fún wọn gbogbo ohun mo ti paláṣẹ fún un. 19 18.19: Ap 3.23.Ẹnikẹ́ni tẹ́̀rọ̀ mi wòlíì náà yóò sọ orúkọ mi, èmi fúnra à mi yóò béèrè lọ́wọ́ rẹ̀. 20 Ṣùgbọ́n wòlíì kan kùgbù sọ ̀rọ̀ kan èmi paláṣẹ fún un láti sọ orúkọ mi tàbí wòlíì ó sọ̀rọ̀ orúkọ ọlọ́run mìíràn, irú wòlíì bẹ́̀ láti ."

21 Ṣùgbọ́n ìwọ ọkàn rẹ , "Báwo ni àwa yóò ṣe mọ ̀rọ̀ Olúwa sọ?" 22 Nígbà ohun wòlíì sọ orúkọ Olúwa ìmúṣẹ tàbí jẹ́ òtítọ́, ìyẹn ni ̀rọ̀ Olúwa sọ, irú wòlíì bẹ́̀ sọ láìwádìí. ṣe bẹ̀rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também