Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 25

1 Nígbà àwọn ènìyàn méjì ń , wọn ẹjọ́ lọ ilé ìdájọ́, àwọn onídàájọ́ ẹjọ́ náà, wọn àre fún aláre àti ̀bi fún ẹlẹ́bi. 2 ó tọ́ láti na ẹlẹ́bi, onídàájọ́ a dọ̀bálẹ̀ a án ojú u rẹ̀ iye pàṣán ó tọ́ ̀ṣẹ̀ ó sẹ̀. 3 Ṣùgbọ́n gbọdọ̀ fún un ju ogójì pàṣán lọ. ó án ju bẹ́̀ lọ, arákùnrin rẹ̀ yóò di ẹni ìrẹ̀sílẹ̀ ojú rẹ̀.

4 25.4: 1Kọ 9.9; 1Tm 5.18. Ìwọ gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.

5 25.5,6: Mt 22.24; Mk 12.19; Lk 20.28. àwọn arákùnrin ń gbé pọ̀, ̀kan nínú wọn , ọmọkùnrin, aya òkú ṣe àlejò ará òde ọkọ rẹ̀. Arákùnrin ọkọ rẹ̀ ni ó wọlé tọ̀ ́, ó fi ṣe aya, ó ṣe iṣẹ́ arákùnrin ọkọ fún un. 6 Ọmọkùnrin ó kọ́ ni yóò máa jẹ́ orúkọ arákùnrin rẹ̀ ó náà, orúkọ rẹ̀ ba á parẹ́ Israẹli.

7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin náà fẹ́ fi aya arákùnrin rẹ̀ ṣe aya rẹ̀, obìnrin náà yóò lọ ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ẹnu-bodè ìlú láti sọ , "Arákùnrin ọkọ ̀ mi kọ̀ láti gbé orúkọ arákùnrin rẹ̀ Israẹli. ṣe ojúṣe rẹ̀ arákùnrin ọkọ mi mi." 8 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀ yóò é, wọn yóò sọ̀rọ̀. ó kọ̀ jálẹ̀ ó sọ , "Èmi fẹ́ láti fẹ́ ," 9 opó arákùnrin rẹ̀ yìí yóò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ojú àwọn àgbàgbà ìlú rẹ̀, yóò yọ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ kan, yóò tu itọ́ ọkùnrin náà lójú, yóò , "Èyí ni ohun a ṣe ọkùnrin jẹ́ ìdílé arákùnrin rẹ̀ títí ayé." 10 A ó mọ ìdílé arákùnrin yìí Israẹli gẹ́gẹ́ "Ìdílé a yọ bàtà rẹ̀."

11 ọkùnrin méjì ń , ìyàwó ̀kan nínú wọn láti gbèjà ọkọ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin ń ú, ó nawọ́ di nǹkan ọkùnrin abẹ́ rẹ̀ . 12 Ìwọ yóò ọwọ́ rẹ̀ náà kúrò. ṣe ṣàánú fún un.

13 25.13-16: Le 19.35,36. ṣe oríṣìí ìtẹ̀wọ̀n méjì yàtọ̀ ara wọn nínú àpò rẹ, ̀kan wúwo àti ̀kan fífúyẹ́. 14 ṣe oríṣìí ìwọ̀n méjì ó yàtọ̀ ara wọn ilé è rẹ: ̀kan fífẹ̀, ̀kan kékeré. 15 O gbọdọ̀ ìtẹ̀wọ̀n àti òsùwọ̀n pípé àti ti òtítọ́ nítorí náà ìwọ ó pẹ́ ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ fún . 16 Nítorí Olúwa Ọlọ́run kórìíra ẹnikẹ́ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí, àní ẹnikẹ́ni ń ṣe àìṣòdodo.

17 25.17-19: Ek 17.14; 1Sa 15. Rántí ohun àwọn ará Amaleki ṣe i yín ̀nígbà ̀ ń jáde láti ilẹ̀ Ejibiti . 18 Nígbà àárẹ̀ un yín agara a yín, wọ́n pàdé e yín ̀àjò o yín, wọ́n àwọn ó rẹ̀yìn kúrò, wọn ìbẹ̀Ọlọ́run. 19 Nígbà Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín ìsinmi lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀yín ó i yín ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run ń fi fún yín láti ni ìní, ̀yin yóò pa ìrántí Amaleki rẹ́ kúrò lábẹ́ ̀run. ṣe gbàgbé.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também