Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 110

Ti Dafidi. Saamu.

1 110.1: Mt 22.44; 26.64; Mk 12.36; 14.62; 16.19; Lk 20.42-43; 22.69; Ap 2.34; 1Kọ 15.25; Ef 1.20; Kl 3.1; Hb 1.3,13; 10.12-13; 12.2. Olúwa sọ fún Olúwa mi ,

"Ìwọ jókòó ọwọ́ ̀tún mi,

títí èmi yóò fi sọ àwọn ̀rẹ

di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ."

2 Olúwa yóò na ̀agbára rẹ̀

láti Sioni , ìwọ jẹ ọba láàrín àwọn ̀rẹ.

3 Àwọn ènìyàn rẹ jẹ́ ̀rẹ́ àtinúwá

ọjọ́ ìjáde ogun rẹ, nínú ẹwà mímọ́,

láti inú òwúrọ̀ ìwọ ni ìrì ẹwà rẹ.

4 110.4: Hb 5.6,10; 6.20; 7.11,15,21. Olúwa ti búra,

í ọkàn padà ,

"Ìwọ ni àlùfáà,

ipasẹ̀ Melkisedeki."

5 Olúwa, ọwọ́ ̀tún rẹ̀ ni

yóò lu àwọn ọba bolẹ̀ ni ọjọ́ ìbínú rẹ̀.

6 Yóò ṣe ìdájọ́ láàrín kèfèrí,

yóò kún ibùgbé wọn pẹ̀òkú ara;

yóò fọ́n àwọn olórí orí ilẹ̀ ayé ó gbòòrò.

7 Yóò mu nínú odò ṣíṣàn ̀:

nítorí náà ni yóò ṣe gbé orí sókè.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também