Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 98

1 kọrin tuntun Olúwa,

nítorí ó ṣe ohun ìyanu;

ọwọ́ ̀tún rẹ̀ àti apá mímọ́ rẹ̀

o ṣe iṣẹ́ ìgbàlà fún un

2 Olúwa ti sọ ìgbàlà rẹ̀ di mọ̀

o fi òdodo rẹ̀ han àwọn orílẹ̀-èdè.

3 Ó rántí ìfẹ́ rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀ fún àwọn ará ilé Israẹli;

gbogbo òpin ayé ni ó ti

iṣẹ́ ìgbàlà Ọlọ́run wa.

4 ìhó ayọ̀ Olúwa, gbogbo ayé,

sáyọ̀, kọrin ìyìn,

5 fi dùùrù kọrin Olúwa, pẹ̀dùùrù àti ìró ohùn orin mímọ́,

6 pẹ̀ìpè àti fèrè

fún ayọ̀ níwájú Olúwa ọba.

7 Jẹ́ òkun ó pẹ̀gbogbo

ohun ó nínú rẹ̀,

Gbogbo ayé àti gbogbo àwọn ń gbé inú rẹ̀.

8 jẹ́ odo ó ṣápẹ́,

jẹ́ òkè ó kọrin pẹ̀ayọ̀;

9 jẹ́ wọn kọrin níwájú Olúwa,

nítorí yóò ṣèdájọ́ ayé

bẹ́̀ ni yóò ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè nínú òdodo

àti àwọn ènìyàn àìṣègbè pẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também