Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 60

Fún adarí orin. ohùn "Lílì ti Májẹ̀." Miktamu ti Dafidi. Fún ìkọ́ni. Nígbà ó Aramu-Naharaimu àti Siria-Soba , àti nígbà Joabu yípadà ó pa ẹgbẹ̀rún méjìlá àwọn ará Edomu àfonífojì Iyọ̀.

1 Ìwọ ti kọ̀ sílẹ̀,

Ọlọ́run, ìwọ ti wa ,

ìwọ ti bínú nísinsin yìí, tún ara rẹ yípadà wa.

2 Ìwọ ti ilẹ̀ wárìrì, ìwọ ti fọ́ ;

fífọ́ rẹ̀ bọ̀ sípò, nítorí ó .

3 Ìwọ ti fi ìgbà ewu han àwọn ènìyàn rẹ;

ìwọ fún wa wáìnì ó máa ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.

4 Àwọn ó bẹ̀rẹ̀, ìwọ fi ̀págun fún

a fihàn nítorí òtítọ́. Sela.

5 60.5-12: Sm 108.6-13. Fi ọwọ́ ̀tún rẹ gbà , o ràn lọ́wọ́,

a gba àwọn o fẹ́ .

6 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀:

"ayọ̀, èmi ó pọ Ṣekemu jáde

èmi ó wọ́n àfonífojì Sukkoti.

7 Tèmi ni Gileadi, tèmi ni Manase;

Efraimu ni àṣíborí mi,

Juda ni ̀àṣẹ mi.

8 Moabu ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi,

lórí Edomu mo bọ́ bàtà mi ;

lórí Filistia ni mo kígbe ayọ̀."

9 Ta ni yóò mi ìlú olódi ?

Ta ni yóò tọ́ lọ Edomu?

10 í ha ń ṣe ìwọ, Ọlọ́run, ó ti kọ̀ sílẹ̀

o ogun wa jáde mọ́?

11 Fún wa ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ̀,

nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.

12 Nípa Ọlọ́run ni a óò ìṣẹ́gun,

yóò tẹ àwọn ̀wa mọ́lẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também