Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 72

Ti Solomoni.

1 Fi ìdájọ́ fún àwọn ọba, Ọlọ́run,

ọmọ-aládé ni ìwọ fi òdodo rẹ fún.

2 Yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀òdodo,

yóò máa fi ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn tálákà rẹ̀.

3 Àwọn òkè ńlá yóò máa àlàáfíà fún àwọn ènìyàn

àti òkè kéékèèké nípa òdodo.

4 Yóò dáàbò bo àwọn a pọ́n lójú láàrín àwọn ènìyàn

yóò gba àwọn ọmọ aláìní;

yóò fa àwọn aninilára ya.

5 Àwọn òtòṣì àti aláìní

yóò máa fi ̀wọ̀ ńlá fún nígbà gbogbo,

níwọ̀n ìgbà oòrùn àti òṣùpá ń ràn,

yóò ti pẹ́ , láti ìrandíran.

6 Yóò dàbí òjò ó ń rọ̀ sórí pápá ìrẹ́mọ́lẹ̀,

ọwọ́ òjò ń rin ilẹ̀.

7 Àwọn olódodo yóò gbilẹ̀ ni ọjọ́ rẹ̀

̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà yóò ;

títí òṣùpá fi mọ́.

8 Yóò máa jẹ ọba láti òkun òkun

àti láti odò Eufurate títí òpin ayé.

9 Àwọn ó aginjù yóò tẹríba fún un

àwọn ̀rẹ̀ yóò máa erùpẹ̀ ilẹ̀.

10 Àwọn ọba Tarṣiṣi àti ti erékùṣù

wọn yóò ọrẹ fún un;

àwọn ọba Ṣeba àti Seba

wọn ó ̀bùn fún un.

11 Gbogbo ọba yóò tẹríba fún un

àti gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sìn ín.

12 Nítorí yóò gba àwọn aláìní

nígbà ó ń ,

tálákà àti ẹni olùrànlọ́wọ́.

13 Yóò káàánú àwọn aláìlera àti aláìní

yóò pa aláìní mọ́ kúrò nínú ikú.

14 Yóò ra ọkàn wọn padà lọ́wọ́ ̀tàn àti ipá

nítorí ̀jẹ̀ wọn ṣọ̀wọ́n níwájú rẹ̀.

15 Yóò pẹ́ ayé!

A ó fún un wúrà Ṣeba.

Àwọn ènìyàn yóò máa gbàdúrà fún un nígbà gbogbo

a bùkún fún un lójoojúmọ́.

16 ìkúnwọ́ ọkà lórí ilẹ̀;

orí òkè ni ó máa dàgbà

èso rẹ̀ o gbilẹ̀ ti Lebanoni

yóò máa gbá yìn i koríko ilẹ̀.

17 orúkọ rẹ̀ ó títí láé;

orúkọ rẹ̀ yóò máa gbilẹ̀ níwọ̀n oòrùn yóò ti pẹ́ .

Wọn ó máa bùkún fún ara wọn nípasẹ̀ rẹ.

Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa alábùkún fún.

18 Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli,

ẹnìkan ṣoṣo ó ń ṣe ohun ìyanu.

19 Olùbùkún ni orúkọ rẹ̀ ó lógo títí láé;

gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.

Àmín àti Àmín.

20 Èyí ni ìparí àdúrà Dafidi ọmọ Jese.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também