Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 2

1 2.1-2: Ap 4.25-26. Èéṣe àwọn orílẹ̀-èdè fi ń dìtẹ̀,

àti àwọn ènìyàn ń ṣe rìkíṣí asán?

2 Àwọn ọba ayé péjọpọ̀

àti àwọn ìjòyè gbìmọ̀ pọ̀

Olúwa àti ẹni àmì òróró rẹ̀.

3 Wọ́n sọ , "jẹ́ a fa ̀wọ̀n wọn ,

a ju ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ wọn ."

4 Ẹni ó gúnwà lórí ìtẹ́ lọ́run rẹ́rìn-ín;

Olúwa fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́.

5 Nígbà náà ni yóò wọn ìbínú rẹ̀

yóò dẹ́rùbà wọ́n ìrunú rẹ̀, ó ,

6 "Èmi ti fi ọba mi ipò

lórí Sioni, òkè mímọ́ mi."

7 2.7: Mt 3.17; Ap 13.33; Hb 1.5; 5.5; 2Pt 1.17. Èmi yóò kéde ìpinnu Olúwa:

Ó sọ fún mi , "Ìwọ ni ọmọ mi;

lónìí, èmi ti di baba rẹ.

8 2.8-9: If 2.26; 12.5; 19.15. Béèrè lọ́wọ́ mi,

Èmi yóò jẹ́ orílẹ̀-èdè di ìní rẹ,

òpin ilé ayé yóò jẹ́ ogún rẹ.

9 Ìwọ yóò fi ̀irin ṣe àkóso wọn

ìwọ yóò rún wọn wómúwómú ìkòkò amọ̀."

10 Nítorí náà, ̀yin ọba, jẹ́ ọlọ́gbọ́n;

gbọ́ ìkìlọ̀ ̀yin alákòóso ayé.

11 sin Olúwa pẹ̀ìbẹ̀

máa yọ̀ pẹ̀ìwárìrì.

12 Fi ẹnu ko ọmọ náà ẹnu, ó ba à bínú,

ó ba à pa yín run ̀yín,

nítorí ìbínú rẹ̀ ru sókè ̀̀kan.

Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn ó fi í ṣe ibi ìsádi wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também