Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 109

Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu.

1 Ọlọ́run, ti èmi ń fi ìyìn fún,

ṣe dákẹ́,

2 nítorí àwọn ènìyàn búburú àti ẹlẹ́tàn

ti ya ẹnu wọn mi

wọ́n ti fi ahọ́n èké sọ̀rọ̀ mi.

3 Wọ́n fi ̀rọ̀ ìríra mi káàkiri;

wọ́n mi láìnídìí

4 Nípò ìfẹ́ mi, wọn ń ṣe ̀mi,

ṣùgbọ́n èmi ń gba àdúrà.

5 Wọ́n fi ibi san ìre fún mi

àti ìríra fún ìfẹ́ mi.

6 Yan àwọn ènìyàn búburú láti dojúkọ

jẹ́ àwọn olùfisùn

dúró ọwọ́ ̀tún rẹ̀.

7 a a lẹ́bi nígbà a ṣe ìdájọ́

àdúrà rẹ̀ ó di ìkọ̀sílẹ̀.

8 109.8: Ap 1.20. ọjọ́ rẹ̀ ó kúrú;

ẹlòmíràn ó rọ́iṣẹ́ rẹ̀.

9 àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìní baba

aya rẹ̀ di opó.

10 Jẹ́ àwọn ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe kiri

wọn máa tọrọ oúnjẹ jìnnà ibi ahoro wọn.

11 Jẹ́ alọ́nilọ́wọ́gbà ó ohun gbogbo ó

jẹ́ àlejò o èrè iṣẹ́ rẹ̀ lọ.

12 ṣe jẹ́ ẹnìkan ṣe àánú fún un

tàbí wọn káàánú lórí

àwọn ọmọ rẹ̀ aláìní baba.

13 a àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ kúrò

orúkọ wọn ó parẹ́ ìran ń bọ̀.

14 ̀ṣẹ̀ àwọn baba rẹ̀

ó ìrántí ̀dọ̀ Olúwa.

ṣe jẹ́ a yọ ̀ṣẹ̀ ìyá wọn kúrò.

15 Jẹ́ ̀ṣẹ̀ wọn ó ìrántí níwájú Olúwa

ó ìrántí wọn kúrò lórí ilẹ̀.

16 Nítorí rántí láti ṣàánú,

ṣùgbọ́n ó ṣe inúnibíni ọkùnrin tálákà àti olùpọ́njú,

ó pa oníròbìnújẹ́ ọkàn.

17 Ó fẹ́ràn láti máa ègún orí rẹ̀:

bi inú rẹ̀ ti dùn si ìre, bẹ́̀ ni ó jìnnà .

18 ó ti fi ègún wọ ará rẹ̀ láṣọ ̀

bẹ́̀ ni ó inú rẹ̀ omi.

19 Jẹ́ ó fún un aṣọ a ó ara,

àti fún àmùrè ó fi gba ̀nígbà gbogbo.

20 Èyí ni èrè àwọn ̀mi láti ọwọ́ Olúwa ;

àti ti àwọn ń sọ̀rọ̀ ibi ọkàn mi.

21 Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ ṣe fún mi Olúwa Olódùmarè,

ṣe rere fún mi nítorí orúkọ rẹ.

Nítorí àánú rẹ dára, ìwọ gbà .

22 Nítorí tálákà àti aláìní ni ,

àyà mi gbọgbẹ́ nínú mi.

23 Èmi ń kọjá lọ òjìji àṣálẹ́,

mo ń gbọ̀n sókè eṣú.

24 Eékún mi di aláìlera nítorí àwẹ̀ gbígbà

ẹran-ara mi gbẹ nítorí àìlera mi.

25 109.25: Mt 27.39; Mk 15.29. Mo dàbí ̀gàn fún àwọn olùfisùn mi;

nígbà wọn , wọ́n gbọn orí wọn.

26 Ràn lọ́wọ́, Olúwa Ọlọ́run mi;

gbà gẹ́gẹ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ.

27 Jẹ́ wọn mọ̀ ọwọ́ rẹ ni èyí

ìwọ, Olúwa, ni ó ṣe é.

28 Wọ́n ó máa gégùn ún, ṣùgbọ́n ìwọ máa súre,

nígbà wọn dìde ojú ó wọ́n,

ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ yóò yọ̀.

29 Jẹ́ a wọ àwọn ̀mi aṣọ ìtìjú

á fi ìdàrúdàpọ̀ bọ̀ wọ́n lára ̀.

30 Pẹ̀ẹnu mi èmi yóò máa yin Olúwa gidigidi

àárín ̀pọ̀ ènìyàn èmi yóò máa yìn ín.

31 Nítorí ó dúró apá ̀tún aláìní

láti gbà á lọ́wọ́ àwọn ń ọkàn rẹ̀ lẹ́bi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também