Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 6

Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin olókùn. Gẹ́gẹ́ ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa, ṣe mi nínú ìbínú rẹ

ìwọ ṣe nínú gbígbóná ìrunú rẹ.

2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń lọ;

Olúwa, sán, nítorí egungun mi nínú ìnira.

3 Ọkàn mi nínú ìrora.

Yóò ti pẹ́ , Olúwa, yóò ti pẹ́ ?

4 Yípadà, Olúwa, o gbà ;

gbà nípa ìfẹ́ rẹ í ṣákì í.

5 Ẹnikẹ́ni ni rántí rẹ nígbà ó .

Ta ni yóò yìn ́ láti inú isà òkú?

6 Agara ìkérora mi mi tán.

Gbogbo òru ni mo wẹ ibùsùn mi pẹ̀ẹkún,

mo fi omi rin ibùsùn mi pẹ̀omijé.

7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀ìbànújẹ́;

wọ́n kùnà nítorí gbogbo ̀mi.

8 6.8: Mt 7.23; Lk 13.27. Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ̀yin ń ṣe iṣẹ́ ibi,

nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe mi.

9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú;

Olúwa ti gba àdúrà mi.

10 Gbogbo àwọn ̀mi lójú yóò , wọn yóò dààmú;

wọn yóò yípadà nínú ìtìjú àìròtẹ́lẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também