Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 11

Fún adarí orin. Ti Dafidi.

1 Ìgbẹ́kẹ̀mi nínú Olúwa.

Báwo ̀yin ó ṣe sọ fún ọkàn mi ,

"gẹ́gẹ́ bi ẹyẹ lọ si orí òkè rẹ.

2 ó nítorí náà, ènìyàn búburú fa ọfà rẹ̀;

wọn ti fi ọfà wọn ojú okùn

láti tafà níbi òjìji

àyà ẹni ìdúró ṣinṣin.

3 Nígbà ìpìlẹ̀ bàjẹ́

ni olódodo yóò ṣe?"

4 Olúwa ń bẹ nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀;

Olúwa ń bẹ lórí ìtẹ́ rẹ̀ ̀run.

Ó ń wo àwọn ọmọ ènìyàn;

ojú rẹ̀ ń yẹ̀ wọ́n .

5 Olúwa ń yẹ olódodo ,

ṣùgbọ́n ènìyàn búburú àti àwọn o fẹ́ ìwà ipá

ni ọkàn rẹ̀ kórìíra.

6 orí àwọn ènìyàn búburú ni yóò rọ̀

̀yín iná àti imí-ọjọ́ ń ;

àti ìjì gbígbóná yóò jẹ ìpín wọn.

7 Nítorí, olódodo Olúwa,

o fẹ́ràn òdodo;

ẹni ìdúró ṣinṣin yóò i.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também