Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 87

Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin.

1 Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;

2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀Sioni

ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.

3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,

ìlú Ọlọ́run,

4 "Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli

láàrín àwọn ó jẹ́wọ́ mi:

Filistia pẹ̀, àti Tire, pẹ̀Kuṣi,

yóò sọ , Èyí ni a Sioni.’ "

5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,

"Eléyìí àti eléyìí ni a nínú rẹ̀,

àti Ọlọ́run ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀."

6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:

"Eléyìí ni a Sioni."

7 Àti àwọn olórin àti àwọn ń lu

ohun èlò orin yóò ,

"Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também