Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 64

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Gbóhùn mi, Ọlọ́run, mo ti ń sọ àròyé mi

pa ọkàn mi mọ́ kúrò lọ́wọ́ ̀àwọn ̀.

2 Pa mọ́ kúrò lọ́wọ́ ìmọ̀ ìkọ̀kọ̀ àwọn ènìyàn búburú

kúrò nínú ̀pọ̀ igbe lọ́wọ́ ìrúkèrúdò oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀.

3 Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn idà,

wọ́n fa ọrun wọn le láti tafà wọn, àní ̀rọ̀ kíkorò.

4 Wọ́n tafà ìkọ̀kọ̀ àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀:

wọ́n tafà si lójijì, wọn bẹ̀.

5 Wọ́n, gba ara wọn níyànjú nínú èrò búburú,

wọ́n sọ̀rọ̀ lórí dídẹkùn sílẹ̀ ìkọ̀kọ̀

wọ́n , "Ta ni yóò wa?"

6 Wọ́n gbìmọ̀ àìṣòdodo, wọ́n ,

"A wa ti parí èrò a gbà tán!"

Lóòótọ́ àyà àti ọkàn ènìyàn kún fún àrékérekè.

7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ta wọ́n ọfà;

wọn ó gbọgbẹ́ lójijì.

8 Ahọ́n wọn yóò dojú ìjà kọ wọ́n, yóò run wọ́n,

gbogbo ẹni ó wọn yóò mi orí fún wọn.

9 Gbogbo ènìyàn yóò máa bẹ̀

wọn ó kéde iṣẹ́ Ọlọ́run

wọn ó dúró ohun ó ṣe.

10 Jẹ́ olódodo ó yọ̀ nínú Olúwa

yóò ààbò nínú rẹ̀.

Gbogbo ẹni ìdúró ṣinṣin ọkàn yóò máa yìn ín.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também