Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 137

1 ̀odò Babeli, níbẹ̀ ni àwa gbé jókòó

àwa sọkún nígbà àwa rántí Sioni.

2 Àwa fi dùùrù wa kọ́ orí igi wílò,

ó láàrín rẹ̀.

3 Nítorí níbẹ̀ ni àwọn

ó wa ìgbèkùn béèrè orin lọ́wọ́ wa,

àti àwọn ó ni lára béèrè ìdárayá;

wọn , "kọ orin Sioni kan fún wa!"

4 Àwa ó ti ṣe kọ orin

Olúwa ilẹ̀ àjèjì

5 Jerusalẹmu, èmi gbàgbé rẹ

jẹ́ ọwọ́ ̀tún mi ó gbàgbé ìlò rẹ̀.

6 èmi rántí rẹ,

jẹ́ ahọ́n mi ó lẹ̀ mọ́ èrìgì mi;

èmi fi Jerusalẹmu ṣáájú

olórí ayọ̀ mi gbogbo.

7 Olúwa rántí ọjọ́ Jerusalẹmu,

lára àwọn ọmọ Edomu,

àwọn ẹni ń ,

"o palẹ̀, o palẹ̀ ìpìlẹ̀ rẹ̀!"

8 Ìwọ, ọmọbìnrin Babeli, ẹni a ó parun;

ìbùkún ni fún ẹni ó san án fún

ìwọ ti wa.

9 Ìbùkún ni fún ẹni ó ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ

ó fi wọ́n ṣán òkúta.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também