Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 70

Fún adarí orin. Ti Dafidi. ̀bẹ̀.

1 70.1-5: Sm 40.13-17. Yára, Ọlọ́run, láti gbà ,

Olúwa, kánkán láti ràn lọ́wọ́.

2 àwọn ń ọkàn mi

a dójútì wọ́n, wọn dààmú;

àwọn ń ìparun mi

̀yìn padà nínú ìtìjú.

3 a pa wọ́n ̀yìn fún èrè

ìtìjú àwọn ń , "Háà! Háà!"

4 Ṣùgbọ́n àwọn ó ń ó máa yọ̀

inú wọn ó máa dùn nípa rẹ,

àwọn ó ń fẹ́ ìgbàlà rẹ máa ,

"Jẹ́ a gbé Ọlọ́run ga!"

5 Ṣùgbọ́n mo jẹ́ òtòṣì àti aláìní;

wa kánkán ̀dọ̀ mi, Ọlọ́run.

Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àti olùdáǹdè mi;

Olúwa, ṣe dúró pẹ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também