Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 58

Fún adarí orin. ohùn "ṣe parun." Ti Dafidi. Miktamu.

1 ̀yin ha ń sọ òdodo nítòótọ́

̀yin ìjọ ènìyàn?

Ǹjẹ́ ̀yin ń ṣe ìdájọ́ ó ṣe títọ́

̀yìn ọmọ ènìyàn?

2 Bẹ́̀ kọ́, nínú ọkàn yín ̀yìn ń gbèrò àìṣòdodo,

ọwọ́ yín ìwà ipá jáde ni ayé.

3 inú ìyá wọn ni ènìyàn búburú ṣìnà,

lójúkan náà a ti wọn, wọn a máa ṣèké.

4 Oró wọn dàbí oró ejò,

wọn dàbí adití ejò paramọ́lẹ̀ ó di ara rẹ̀ ni etí,

5 gbọ́ ìpè àwọn atunilójú,

ó ti ó máa fi ọgbọ́n ṣe ìtujú .

6 eyín ẹnu wọn, Ọlọ́run;

ẹnu wọn,

̀gàn àwọn ọmọ kìnnìún, Olúwa.

7 Jẹ́ wọn parẹ́ omi ń sàn lọ;

nígbà ó fa ọfà rẹ̀, ̀kọ̀ wọn ó ṣẹ́.

8 Jẹ́ wọn ìgbín rẹ̀ dànù ó ṣègbé

ọmọ oṣù rẹ̀ , wọn ṣe oòrùn.

9 ìkòkò yín ó mọ ìgbóná ̀gún;

bóyá tútù tàbí gbígbẹ, yóò fi ìjì gbá wọn lọ.

10 Olódodo yóò yọ̀ nígbà a ń gbẹ̀san wọn,

nígbà wọn wẹ ẹsẹ̀ wọn nínú ̀jẹ̀ ènìyàn búburú.

11 Àwọn ènìyàn yóò ,

"Lóòtítọ́ èrè àwọn ń bẹ fún olódodo;

lóòtítọ́ òun ni Ọlọ́run ń ṣe ìdájọ́ ayé."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também