Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 10

Ìjẹ́wọ́ ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn

1 Nígbà Esra ń gbàdúrà ó ń jẹ́wọ́, ti ó ń sọkún ti ó ń gbárayílẹ̀ níwájú ilé Ọlọ́run, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé pagbo i . Àwọn náà ń sọkún kíkorò. 2 Nígbà náà ni Ṣekaniah ọmọ Jehieli, ̀kan lára ìran Elamu, sọ fún Esra , "Àwa ti jẹ́ aláìṣòótọ́ Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì láàrín àwọn ènìyàn ó wa . Ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, ìrètí fún Israẹli 3 Nísìnsinyìí, jẹ́ a májẹ̀níwájú Ọlọ́run wa láti àwọn obìnrin yìí àti àwọn ọmọ wọn lọ. Gẹ́gẹ́ ìmọ̀ràn Esra olúwa mi àti ti àwọn ó bẹ̀àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa. jẹ́ a ṣe gẹ́gẹ́ òfin. 4 Dìde, nítorí, ̀rọ̀ tìrẹ ni èyí. Gbogbo yóò pẹ̀rẹ, ọkàn le o ṣe é."

5 Nígbà náà ni Esra dìde, ó fi àwọn aṣíwájú àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo Israẹli abẹ́ ìbúra, láti ṣe ohun wọ́n lábàá. Wọ́n búra. 6 Nígbà náà ni Esra padà sẹ́yìn kúrò níwájú ilé Ọlọ́run, ó lọ iyàrá Jehohanani ọmọ Eliaṣibu. Nígbà ó níbẹ̀, jẹ oúnjẹ bẹ́̀ ni mu omi, nítorí ó ń káàánú fún àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn.

7 Ìkéde kan jáde lọ jákèjádò Juda àti Jerusalẹmu fún gbogbo àwọn ìgbèkùn láti péjọ Jerusalẹmu. 8 Ẹnikẹ́ni ó ba kọ̀ láti jáde láàrín ọjọ́ mẹ́ta yóò pàdánù ohun ìní rẹ̀ ìbámu pẹ̀ìpinnu àwọn ìjòyè àti àwọn àgbàgbà, àti a ó òun fúnra rẹ̀ jáde kúrò láàrín ìpéjọpọ̀ àwọn ìgbèkùn.

9 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta náà, gbogbo àwọn ọkùnrin Juda àti Benjamini péjọ Jerusalẹmu. ogúnjọ́ oṣù kẹsànán, gbogbo àwọn ènìyàn jókòó ìta gbangba iwájú ilé Ọlọ́run, wọ́n nínú ìbànújẹ́ ńlá nítorí ̀ràn yìí, àti nítorí òjò púpọ̀ rọ̀. 10 Nígbà náà ni àlùfáà Esra dìde, ó fún wọn , "̀yin ti ṣe àìṣòótọ́, ti fẹ́ obìnrin àjèjì, ti kún ̀bi Israẹli. 11 Nísinsin yìí, jẹ́wọ́ níwájú Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba yín, ṣe ìfẹ́ rẹ̀. ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn ó i yín àti láàrín àwọn ìyàwó àjèjì yín."

12 Àpéjọpọ̀ ènìyàn náà dáhùn lóhùn rara , ohun ó sọ dára! A gbọdọ̀ ṣe o ti . 13 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ ni ó ni ibi yìí síbẹ̀ àkókò òjò ni; àwa dúró ìta. Yàtọ̀ èyí, a le è yanjú ̀rọ̀ yìí láàrín ọjọ́ kan tàbí ọjọ́ méjì, nítorí ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ jọjọ lórí àwọn nǹkan wọ̀nyí. 14 Jẹ́ àwọn ìjòyè wa ṣojú fún gbogbo ìjọ ènìyàn, lẹ́yìn náà, jẹ́ ẹnìkọ̀̀kan nínú àwọn ìlú wa ó ti fẹ́ obìnrin àjèjì àsìkò a yàn, pẹ̀àwọn àgbàgbà àti àwọn onídàájọ́ ìlú kọ̀̀kan, títí ìbínú gíga Ọlọ́run wa lórí ̀rọ̀ yìí yóò fi kúrò orí wa. 15 Jonatani ọmọ Asaheli àti Jahseiah ọmọ Tikfa nìkan pẹ̀àtìlẹ́yìn Meṣullamu àti Ṣabbetai ará Lefi, ni wọ́n tako àbá yìí.

16 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ṣe gẹ́gẹ́ wọ́n ṣe fi ẹnu . Àlùfáà Esra yan àwọn ọkùnrin wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé, ẹnìkọ̀̀kan láti ìdílé kọ̀̀kan, gbogbo wọn ni a mọ̀ pẹ̀orúkọ wọn. ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, wọ́n jókòó láti ṣe àyẹ̀àwọn ẹjọ́ náà, 17 ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni wọn parí pẹ̀àwọn ènìyàn wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.

Àwọn jẹ̀bi ̀sùn ìgbéyàwó pẹ̀àjèjì

18 Lára ìran àwọn àlùfáà àwọn wọ̀nyí fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.

Nínú ìran Jeṣua ọmọ Josadaki, àti àwọn arákùnrin rẹ:

Maaseiah, Elieseri, Jaribi àti Gedaliah. 19 Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìpinnu láti àwọn ìyàwó wọn lọ, wọ́n fi àgbò kan láàrín agbo ẹran lélẹ̀ fún ̀bi wọn gẹ́gẹ́ ọrẹ ̀ṣẹ̀.

20 Nínú ìran Immeri:

Hanani àti Sebadiah.

21 Nínú ìran Harimu:

Maaseiah, Elijah, Ṣemaiah, Jehieli àti Ussiah.

22 Nínú ìran Paṣuri:

Elioenai, Maaseiah, Iṣmaeli, Netaneli, Josabadi àti Eleasa.

23 Lára àwọn ọmọ Lefi:

Josabadi, Ṣimei, Kelaiah (èyí í ṣe Kelita), Petahiah, Juda àti Elieseri.

24 Nínú àwọn akọrin:

Eliaṣibu.

Nínú àwọn aṣọ́:

Ṣallumu, Telemu àti Uri.

25 Àti lára àwọn ọmọ Israẹli tókù.

Nínú ìran Paroṣi:

Ramiah, Issiah, Malkiah, Mijamini, Eleasari, Malkiah àti Benaiah.

26 Nínú ìran Elamu:

Mattaniah, Sekariah, Jehieli, Abdi, Jerimoti àti Elijah.

27 Nínú àwọn ìran Sattu:

Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, Jerimoti, Sabadi àti Asisa.

28 Nínú àwọn ìran Bebai:

Jehohanani, Hananiah, Sabbai àti Atlai.

29 Nínú àwọn ìran Bani:

Meṣullamu, Malluki, Adaiah, Jaṣubu, Ṣeali àti Jerimoti.

30 Nínú àwọn Pahati-Moabu:

Adma, Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleli, Binnui àti Manase.

31 Nínú àwọn ìran Harimu:

Elieseri, Iṣiah, Malkiah àti Ṣemaiah, Simeoni, 32 Benjamini, Malluki àti Ṣemariah.

33 Nínú àwọn ìran Haṣumu:

Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifaleti, Jeremai, Manase àti Ṣimei.

34 Nínú àwọn ìran Bani:

Maadai, Amramu, Ueli, 35 Benaiah, Bediah, Keluhi 36 Faniah, Meremoti, Eliaṣibu, 37 Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.

38 Àti Bani, àti Binnui:

Ṣimei, 39 Ṣelemiah, Natani, Adaiah, 40 Maknadebai, Sasai, Ṣarai, 41 Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah, 42 Ṣallumu, Amariah àti Josẹfu.

43 Nínú àwọn ìran Nebo:

Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Sebina, Jaddai, Joẹli àti Benaiah.

44 Gbogbo àwọn wọ̀nyí fẹ́ obìnrin àjèjì, àwọn mìíràn nínú wọn bi ọmọ ipasẹ̀ àwọn ìyàwó wọ̀nyí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também