Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 1

Kirusi ran àwọn a nígbèkùn lọ́wọ́ láti padà

1 1.1-3: Es 5.13; 6.3; 2Ki 36.22,23. ọdún kìn-ín-ní Kirusi, ọba Persia, a ̀rọ̀ Olúwa Jeremiah sọ ṣẹ, Olúwa ru ọkàn Kirusi ọba Persia sókè láti ṣe ìkéde jákèjádò gbogbo agbègbè ìjọba rẹ̀, ó ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ ,

2 "Èyí ni ohun Kirusi ọba Persia :

" Olúwa, Ọlọ́run ̀run, ti fún mi gbogbo ìjọba ayé. Ó ti yàn láti kọ́ tẹmpili Olúwa fún un Jerusalẹmu ó Juda. 3 Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yínỌlọ́run rẹ̀ pẹ̀rẹ̀, ó gòkè lọ Jerusalẹmu ó Juda, láti kọ́ tẹmpili Olúwa Ọlọ́run Israẹli, Ọlọ́run ó Jerusalẹmu. 4 àwọn ènìyàn ibikíbi ẹni náà ń gbé ó fi fàdákà àti wúrà pẹ̀ohun ó dára àti ẹran ̀sìn, pẹ̀ọrẹ àtinúwá ràn án lọ́wọ́ fún tẹmpili Ọlọ́run Jerusalẹmu.’ "

5 Nígbà náà àwọn olórí ìdílé Juda àti Benjamini àti àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefiolúkúlùkù ẹni Ọlọ́run ti fọwọ́ tọ́ ọkàn rẹ̀—múra láti gòkè lọ láti kọ ilé Olúwa Jerusalẹmu. 6 Gbogbo àwọn aládùúgbò wọn ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹ̀ohun èlò ti fàdákà àti wúrà, pẹ̀onírúurú ohun ìní àti ẹran ̀sìn àti pẹ̀àwọn ̀bùn iyebíye, àfikún si gbogbo àwọn ọrẹ àtinúwá.

7 àfikún, ọba Kirusi àwọn ohun èlò ó jẹ́ ti ilé Olúwa jáde , Nebukadnessari ti lọ láti Jerusalẹmu ó ti ilé òrìṣà rẹ̀. 8 Kirusi ọba Persia pàṣẹ fún Mitredati olùṣọ́ ilé ìṣúra láti wọn jáde, ó wọ́n fún Ṣeṣbassari ìjòyè Juda.

9 Èyí ni iye wọn.

Ọgbọ̀n àwo wúrà 30

Ẹgbẹ̀rún àwo fàdákà 1,000

Àwo ìrúbọ fàdákà mọ́kàndínlọ́gbọ̀n 29

10 Ọgbọ̀n àdému wúrà 30

Irinwó ó mẹ́wàá oríṣìí àdému fàdákà mìíràn 410

Ẹgbẹ̀rún kan àwọn ohun èlò mìíràn 1,000

11 Gbogbo ohun èlò wúrà àti ti fàdákà àpapọ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ó irinwó (5,400).

Ṣeṣbassari gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí pẹ̀àwọn ìgbèkùn ó gòkè láti Babeli Jerusalẹmu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também