Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 36

1 36.1-4: 2Ọb 23.30-34. Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà Jehoahasi ọmọ Josiah wọn fi jẹ ọba Jerusalẹmu ni ipò baba rẹ̀.

Jehoahasi ọba Juda

2 Jehoahasi jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógún nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta. 3 Ọba Ejibiti yọ kúrò lórí ìtẹ́ Jerusalẹmu, ó fún un lórí Juda, ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì fàdákà àti tálẹ́ǹtì wúrà kan. 4 Ọba Ejibiti Eliakimu, arákùnrin Joahasi, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu, ó orúkọ Eliakimu padà Jehoiakimu, ṣùgbọ́n Neko Joahasi arákùnrin Eliakimu lọ Ejibiti.

Jehoiakimu ọba Juda

5 36.5-8: 2Ọb 23.36–24.6. Jehoiakimu jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún méjìlá. Ó ṣe búburú ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. 6 Nebukadnessari ọba Babeli un, ó é pẹ̀̀wọ̀n láti un lọ Babeli. 7 Nebukadnessari nínú ohun èlò ilé Olúwa lọ si Babeli pẹ̀, ó fi wọn ààfin rẹ̀ Babeli.

8 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoiakimu, àwọn ohun ìríra ó ṣe àti gbogbo ohun a nípa rẹ̀, ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Israẹli àti Juda. Jehoiakini ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Jehoiakini ọba Juda

9 36.9-10: 2Ọb 24.8-17. Jehoiakini jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlógún nígbà ó di ọba, ó jẹ́ ọba Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta àti ọjọ́ mẹ́wàá ó ṣe búburú ojú Olúwa. 10 àkókò òjò, ọba Nebukadnessari ránṣẹ́ i ó un Babeli, pẹ̀ohun èlò dáradára láti ilé Olúwa, ó arákùnrin Jehoiakini, Sedekiah, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu.

Sedekiah ọba Juda

11 Sedekiah jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlá. 12 Ó ṣe búburú ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Jeremiah wòlíì ẹni ó sọ̀rọ̀ Olúwa. 13 Ó tún ṣọ̀tẹ̀ ọba Nebukadnessari pẹ̀, ẹni ó ó fi orúkọ Ọlọ́run búra. Ó di ọlọ́run líle, ó ọkàn rẹ̀ le láti yípadà Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 14 Síwájú i gbogbo àwọn olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn di ẹni ń dẹ́ṣẹ̀ gidigidi, pẹ̀gbogbo ìríra àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n sọ ilé Olúwa di èérí, ó ti mímọ́ Jerusalẹmu.

Ìṣubú Jerusalẹmu

15 Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn ránṣẹ́ wọn láti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ síwájú àti síwájú i, nítorí ó ìyọ́àwọn ènìyàn rẹ̀ àti ibùgbé rẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n wọ́n ń kùn àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run, wọ́n kẹ́gàn ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n fi àwọn wòlíì rẹ̀ ṣẹ̀sín títí ìbínú Olúwa fi ru sórí wọn, àwọn ènìyàn rẹ̀ ṣí àtúnṣe. 17 Ó sórí wọn ọba àwọn ará Babeli wọ́n àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọn pẹ̀idà ilẹ̀ ibi mímọ́, ìyọ́àgbà ọkùnrin tàbí ̀dọ́mọdébìnrin, wúńdíá, tàbí arúgbó. Ọlọ́run fi gbogbo wọn Nebukadnessari lọ́wọ́. 18 Ó gbogbo ohun èlò láti ilé Ọlọ́run lọ Babeli, ńlá àti kékeré àti ìṣúra ilé Olúwa àti ìṣúra ọba àti ìjòyè rẹ̀. 19 Wọ́n fi iná sun ilé Ọlọ́run, wọ́n gbogbo ògiri ilé Jerusalẹmu, wọ́n gbogbo ààfin wọn, wọ́n ba gbogbo ohun èlò ibẹ̀ jẹ́.

20 Ó èyí ó lọ Babeli àwọn ó ibi kúrò lẹ́nu idà wọ́n di ìránṣẹ́ fún un àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí ìjọba Persia fi gba agbára. 21 Ilẹ̀ náà gbádùn ìsinmi rẹ̀, gbogbo ìgbà ìdahoro, òun ń sinmi títí àádọ́rin ọdún fi ìmúṣẹ ̀rọ̀ Olúwa a sọ láti ẹnu Jeremiah.

22 36.22,23: Es 1.1-3. ọdún kìn-ín-ní Kirusi ọba Persia, ̀rọ̀ Olúwa a tẹnu Jeremiah sọ à le ṣẹ , Olúwa run ̀Kirusi ọba Persia láti ṣe ìkéde gbogbo ìjọba rẹ̀, ó kọ ́ sínú ìwé pẹ̀.

23 "Èyí ni ohun Kirusi ọba Persia sọ :

" Olúwa, Ọlọ́run ̀run, ti fún gbogbo ìjọba ayé yìí, ó ti yàn láti kọ́ ilé Olúwa fún òun Jerusalẹmu ti Juda. Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yín le gòkè lọ pẹ̀rẹ̀; Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ ó pẹ̀rẹ̀.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também