Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 21

1 21.1: 1Ọb 22.50. Nígbà náà Jehoṣafati sùn pẹ̀àwọn baba a rẹ̀, a sin ín pẹ̀wọn ìlú ńlá Dafidi. Jehoramu ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba. 2 Àwọn arákùnrin Jehoramu ọmọ Jehoṣafati jẹ́ Asariah, Jehieli, Sekariah. Asariahu, Mikaeli àti Ṣefatia. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Jehoṣafati ọba Israẹli. 3 Baba wọn ti fún wọn ̀bùn púpọ̀ ti fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò iyebíye pẹ̀àwọn ìlú ààbò Juda, ṣùgbọ́n, ó ti gbé ìjọba fún Jehoramu nítorí òun ni àkọ́ọmọkùnrin.

Jehoramu ọba Juda

4 Nígbà Jehoramu fi ẹsẹ̀ rẹ̀ múlẹ̀ gidigidi lórí ìjọba baba a rẹ̀, ó fi idà pa gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli. 5 21.5-10: 2Ọb 8.17-22.Jehoramu jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ. 6 Ó rìn ̀àwọn ọba Israẹli gẹ́gẹ́ ìdílé Ahabu ti ṣe, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu. Ó ṣe búburú lójú Olúwa. 7 ó tilẹ̀ bẹ́̀, nítorí májẹ̀Olúwa ti fún Dafidi í ṣe ìfẹ́ Olúwa láti pa ìdílé Dafidi run ó ti ṣe ìlérí láti tọ́fìtílà kan fún un àti àwọn àtẹ̀rẹ̀ títí láé.

8 àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ Juda, wọ́n gbé ọba tiwọn kalẹ̀. 9 Bẹ́̀ ni, Jehoramu lọ síbẹ̀ pẹ̀àwọn ìjòyè rẹ̀ àti gbogbo àwọn kẹ̀kẹ́. Àwọn ará Edomu i àti àwọn alákòóso àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Ṣùgbọ́n ó dìde òru ó ṣẹ́gun wọn òru. 10 Títí di ọjọ́ òní ni Edomu ti ìṣọ̀tẹ̀ Juda.

Libina ṣọ̀tẹ̀ àkọ́kọ́ náà, nítorí Jehoramu ti kọ Olúwa sílẹ̀, Ọlọ́run àwọn baba a rẹ̀. 11 Òun pẹ̀ti kọ́ àwọn ibi gíga lórí àwọn òkè Juda. Ó ti á àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ó ṣe àgbèrè pẹ̀ara wọn. Ó ti jẹ́ wọn ó ṣáko lọ.

12 Jehoramu gba ìwé láti ọwọ́ Elijah wòlíì, ó ,

"Èyí ohun Olúwa, Ọlọ́run baba à rẹ Dafidi : Ìwọ ì rìn ̀àwọn baba à rẹ Jehoṣafati tàbí Asa ọba Juda. 13 Ṣùgbọ́n ìwọ ti rìn ̀àwọn ọba Israẹli, ìwọ ti tọ́ Juda àti àwọn ènìyàn Jerusalẹmu láti ṣe àgbèrè ara wọn, gẹ́gẹ́ ilé Ahabu ti ṣe. Ìwọ ti pa àwọn arákùnrin rẹ, ̀ara ilé baba à rẹ, àwọn ọkùnrin ó dára ́ lọ. 14 Bẹ́̀ ni nísinsin yìí, Olúwa ti fẹ́rẹ lu àwọn ènìyàn rẹ, àwọn ọmọ rẹ, àwọn ìyàwó rẹ àti gbogbo ohun ó jẹ́ tìrẹ, pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn ńlá. 15 Ìwọ tìkára yóò ṣe àárẹ̀ pẹ̀àìsàn lílọ́ra ti ìfun, títí àìsàn náà yóò fi jẹ́ àwọn ìfun rẹ jáde ìta.’ "

16 Olúwa ru ìbínú àwọn ará Filistini àti àwọn Arabia wọ́n ń gbé ̀àwọn ará Kuṣi Jehoramu. 17 Wọ́n dojú ìjà kọ Juda, wọ́n gbà á, wọ́n gbogbo ọrọ̀ a ilé ọba pẹ̀, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ àti àwọn ọmọkùnrin kankan sílẹ̀ fún un ṣe Ahasiah, àbíkẹ́yìn nínú àwọn ọmọ rẹ̀.

18 Lẹ́yìn gbogbo èyí, Olúwa jẹ Jehoramu pẹ̀ààrùn ṣe é wòsàn nínú ìfun. 19 àkókò kan ìparí ọdún kejì, àwọn ìfun rẹ̀ jáde nítorí ààrùn náà ó nínú ìrora ńlá. Àwọn ènìyàn rẹ̀ iná láti fi bu ọlá fún un, gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe fún àwọn baba a rẹ̀.

20 21.20: 2Ọb 8.17,24. Jehoramu jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n ìgbà ó di ọba, Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ. Ó kọjá lọ, ẹni ó kábámọ̀. A sin ín si ìlú ńlá ti Dafidi. Ṣùgbọ́n í ṣe nínú ibojì àwọn ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também