Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 23

1 ọdún keje, Jehoiada fi agbára rẹ̀ hàn. O májẹ̀pẹ̀àwọn alákòóso ̀rọ̀̀rún kan, Asariah ọmọ Jerohamu, Iṣmaeli ọmọ Jehohanani Asariah ọmọ Obedi, Maaseiah ọmọ Adaiah àti Elisafati ọmọ Sikri. 2 Wọ́n lọ gbogbo Juda, wọ́n pe àwọn ará Lefi àti àwọn olórí àwọn ìdílé àwọn ará Israẹli láti gbogbo àwọn ìlú jọ. Nígbà wọ́n Jerusalẹmu. 3 Gbogbo ìpéjọ náà májẹ̀pẹ̀ọba ilé Ọlọ́run.

Jehoiada fún wọn , "Ọmọkùnrin ọba yóò jẹ ọba, Olúwa ti ṣèlérí nípa àwọn ìran Dafidi. 4 Nísinsin yìí èyí ni ohun ó yẹ ó ṣe, ìdámẹ́ta àlùfáà yín àti àwọn ará Lefi ó ń lọ fún iṣẹ́ ìsìn ọjọ́ ìsinmi ni ó bojútó àwọn ìlẹ̀kùn. 5 Ìdámẹ́ta yín níbi ààfin ọba àti ìdámẹ́ta níbi ẹnu odi ìdásílẹ̀ àti gbogbo ọkùnrin mìíràn ni ó àgbàlá ààfin ilé Olúwa. 6 ẹnìkan ó gbọdọ̀ wọ inú ilé Olúwa yàtọ̀ àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi a rán iṣẹ́ ìsìn. Wọ́n wọlé nítorí a ti wọ́n sọ́tọ̀, ṣùgbọ́n gbogbo ọkùnrin mìíràn ni wọn ó sọ ohun Olúwa ti yàn fún wọn. 7 Àwọn ará Lefi gbọdọ̀ ìdúró ṣinṣin ọba . Olúkúlùkù pẹ̀àwọn nǹkan ìjà ọwọ́ rẹ̀. Ẹnikẹ́ni ó wọ ilé Olúwa ni pa. dúró ti ọba níbikíbi ó lọ."

8 Àwọn ará Lefi àti gbogbo ọkùnrin Juda ṣe gẹ́gẹ́ Jehoiada àlùfáà ti paláṣẹ. Olúkúlùkù àwọn ọkùnrin rẹ̀, àwọn wọ́n lọ fún iṣẹ́ ìsìn ọjọ́ ìsinmi àti àwọn wọ́n ń kúrò ibi iṣẹ́. Nítorí Jehoiada àlùfáà ì ìpín kankan sílẹ̀. 9 Jehoiada àlùfáà, fi ̀kọ̀ àti asà, àti àpáta wọ̀n-ọn-nì, ó jẹ́ ti ọba Dafidi wọn ilé Ọlọ́run, fún àwọn balógun ̀rọ̀̀rún. 10 Ó to gbogbo àwọn ènìyàn ti ọba káàkiri, olúkúlùkù pẹ̀ohun ìjà rẹ̀ ọwọ́ rẹ̀, láti apá ̀tún ilé náà títí apá òsì ilé náà, lẹ́bàá pẹpẹ àti lẹ́bàá ilé náà.

11 Jehoiada àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ ọmọkùnrin ọba jáde wọ́n gbé adé sórí rẹ̀; wọ́n ̀májẹ̀kan fún un. Wọ́n kéde rẹ̀ lọ́ba. Wọ́n fi àmì òróró yàn án, wọ́n kígbe , "ọba ó pẹ́!"

12 Nígbà Ataliah gbọ́ igbe àwọn ènìyàn wọ́n ń sáré wọ́n ń kígbe ọba, ó lọ ̀dọ̀ wọn ilé Olúwa. 13 Ó , kíyèsi, ọba dúró ibùdó rẹ̀ ̀ẹnu-ọ̀, àti àwọn balógun àti àwọn afùnpè lọ́dọ̀ ọba, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yọ̀, wọ́n fọn ìpè, àti àwọn akọrin pẹ̀ohun èlò ìyìn. Nígbà náà ni Ataliah fa aṣọ rẹ̀ ya, ó kégbe , "̀tẹ̀! ̀tẹ̀!"

14 Jehoiada àlùfáà àwọn alákòóso ̀rọ̀̀rún, ó àbojútó àwọn ̀wọ́ ogun, ó fún wọn , "un jáde láàrín àwọn ọgbà, a fi idà pa ẹnikẹ́ni ó tẹ̀." Nítorí àlùfáà ti , "ṣe pa á nínú ilé Olúwa." 15 Bẹ́̀ ni wọ́n fi ipá un ó ẹnu-ọ̀àbáwọlé ẹṣin ti ilé ọba, wọ́n ti pa á níbẹ̀.

16 Nígbà náà ni Jehoiada, májẹ̀òun àti àwọn ènìyàn àti ọba yóò jẹ́ ènìyàn Olúwa. 17 Gbogbo àwọn ènìyàn lọ ilé Baali, wọ́n á ya lulẹ̀. Wọ́n fọ́ àwọn pẹpẹ àti àwọn òrìṣà, wọ́n pa Mattani àlùfáà Baali níwájú àwọn pẹpẹ.

18 Nígbà náà, Jehoiada tẹ àwòrán ilé Olúwa ọwọ́ àwọn àlùfáà wọ́n jẹ́ ará Lefi ẹni Dafidi ti fi ṣe iṣẹ́ ilé Olúwa láti tẹ ẹbọ sísun ti Olúwa a ti kọ ́ nínú òfin Mose, pẹ̀ayọ̀ àti orin kíkọ, gẹ́gẹ́ Dafidi ti pàṣẹ. 19 Ó àwọn olùṣọ́ni ipò ìdúró ẹnu odi ilé Olúwa ẹni aláìmọ́ nínú ohunkóhun ba à wọlé.

20 Ó pẹ̀rẹ̀ àwọn alákòóso ̀rọ̀̀rún, àwọn ẹni ọlá, àwọn olórí àwọn ènìyàn àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà. Ó ọba sọ̀kalẹ̀ láti ilé Olúwa. Wọ́n lọ sínú ààfin láti ẹnu òde ti òkè. Wọ́n fi ọba jókòó lórí ìtẹ́. 21 Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yọ̀, ìlú náà dákẹ́ rọ́rọ́. Nítorí a pa Ataliah pẹ̀idà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também