Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 29

Hesekiah sọ ilé Olúwa di mímọ́

1 29.1,2: 2Ọb 18.1-3. Hesekiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n orúkọ ìyá rẹ̀ ni Abijah ọmọbìnrin Sekariah. 2 Ó ṣe ohun ó tọ́ ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ baba rẹ̀ Dafidi ti ṣe.

3 oṣù àkọ́kọ́ ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, ó ṣí àwọn ìlẹ̀kùn ilé Olúwa ó tún wọn ṣe. 4 Ó àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, ó wọn jọ yíká ìta ìlà-oòrùn. 5 Ó , "gbọ́ tèmi, ̀yin ọmọ Lefi! ya ara yín mímọ́ nísinsin yìí ya ilé Olúwa Ọlọ́run mímọ́, ohun àìmọ́ baba mi jáde kúrò ibi mímọ́. 6 Àwọn baba wa jẹ́ aláìṣòótọ́; wọ́n ṣe ohun àìtọ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run wa, wọ́n kọ̀ ́ sílẹ̀. Wọ́n ojú wọn padà kúrò ibùgbé Olúwa, wọ́n pa ̀yìn wọn i. 7 Wọ́n tún ti ìlẹ̀kùn ìloro náà pẹ̀, wọ́n pa fìtílà. Wọn sun tùràrí tàbí pèsè ẹbọ sísun si ibi mímọ́ si Ọlọ́run Israẹli. 8 Nítorí náà, ìbínú Olúwa ti ru sókè sórí Juda àti Jerusalẹmu ó ti fi wọ́n ṣe ohun èlò fún wàhálà, àti ìdààmú àti ̀sín, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe fi ojú rẹ̀ i. 9 Ìdí nìyí àwọn baba wa ṣe ṣubú nípa idà àti ìdí àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin àti àwọn aya wa tiwọn wọ́n ìgbèkùn. 10 Nísinsin yìí ó ọkàn mi láti Olúwa Ọlọ́run Israẹli májẹ̀. Bẹ́̀ ni ìbínú rẹ̀ kíkan ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa. 11 Àwọn ọmọ mi, ṣe jáfara nísinsin yìí, nítorí Olúwa ti yàn yín láti dúró níwájú rẹ̀ láti sin, máa ṣe ìránṣẹ́ níwájú rẹ̀ àti láti sun tùràrí."

12 Nígbà náà àwọn ọmọ Lefi wọ̀nyí múra láti ṣe iṣẹ́:

nínú àwọn ọmọ Kohati,

Mahati ọmọ Amasai: àti Joẹli ọmọ Asariah;

nínú àwọn ọmọ Merari,

Kiṣi ọmọ Abdi àti Asariah ọmọ Jehaleeli;

nínú àwọn ọmọ Gerṣoni,

Joah, ọmọ Simma àti Edeni ọmọ Joah;

13 nínú àwọn ọmọ Elisafani,

Ṣimri àti Jeieli;

nínú àwọn ọmọ Asafu,

Sekariah àti Mattaniah;

14 nínú àwọn ọmọ Hemani,

Jehieli àti Ṣimei;

nínú àwọn ọmọ Jedutuni,

Ṣemaiah àti Usieli.

15 Nígbà wọ́n ti ara wọn jọ pọ̀ pẹ̀àwọn arákùnrin wọn, wọ́n ya ara wọn mímọ́, wọ́n lọ láti gbá ilé Olúwa mọ́, gẹ́gẹ́ ọba ti pa á láṣẹ, tẹ̀̀rọ̀ Olúwa. 16 Àwọn àlùfáà wọ inú ilé Olúwa lọ́hùn ún lọ láti gbá a mọ́. Wọ́n gbé e jáde inú àgbàlá ilé Olúwa gbogbo ohun àìmọ́ wọ́n nínú ilé Olúwa. Àwọn ọmọ Lefi u wọ́n gbangba odò Kidironi. 17 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìyàsímímọ́ ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní, àti ọjọ́ kẹjọ oṣù náà wọ́n ìloro Olúwa. Fún ọjọ́ mẹ́jọ mìíràn i, wọ́n ya ilé Olúwa mímọ́ fúnra rẹ̀. Wọ́n parí ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù kìn-ín-ní.

18 Nígbà náà wọn lọ ̀dọ̀ ọba Hesekiah láti lọ jábọ̀ fún un: "Àwa ti gbá ilé Olúwa mọ́, pẹpẹ ẹbọ sísun pẹ̀gbogbo ohun ẹbọ rẹ̀, àti tábìlì àkàrà ìfihàn, pẹ̀gbogbo ohun èlò. 19 A ti pèsè a ti mímọ́ gbogbo ohun èlò ọba Ahasi ti sọ di aláìmọ́ nínú àìṣòótọ́ rẹ̀ nígbà ó jẹ́ ọba; nísinsin yìí, wọ́n níwájú pẹpẹ Olúwa."

20 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ọba Hesekiah olórí àwọn ìjòyè jọ, ó lọ sókè ilé Olúwa. 21 Wọ́n akọ màlúù méje , àti àgbò méje, àti ̀dọ́-àgùntàn méje àti òbúkọ méje gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ fún ìjọba, fún ibi mímọ́ àti fún Juda. Ọba pàṣẹ fun àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Aaroni, láti ṣe èyí lórí pẹpẹ Olúwa. 22 Bẹ́̀ ni wọ́n pa akọ màlúù, àwọn àlùfáà ̀jẹ̀ náà, wọ́n fi wọ́n ara pẹpẹ. Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni nígbà wọ́n pa àgbò, wọ́n fi ̀jẹ̀ wọ́n orí pẹpẹ. Nígbà náà wọ́n pa ̀dọ́-àgùntàn, wọ́n fi ̀jẹ̀ wọn ara pẹpẹ. 23 Òbúkọ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni wọ́n gbé síwájú ọba àti ìjọ ènìyàn, wọ́n gbé ọwọ́ wọn. 24 Àwọn àlùfáà wọn pa òbúkọ, wọ́n gbé ̀jẹ̀ kalẹ̀ lórí pẹpẹ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún gbogbo Israẹli, nítorí ọba ti pàṣẹ a ṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ̀ṣẹ̀ fún gbogbo Israẹli.

25 Ó àwọn Lefi dúró nínú ilé Olúwa pẹ̀Kimbali, ohun èlò orin olókùn àti dùùrù ̀a ti paláṣẹ fún wọn láti ̀dọ̀ Dafidi àti Gadi aríran ọba àti Natani wòlíì. Èyí ni a pàṣẹ láti ̀dọ̀ Olúwa láti ọwọ́ àwọn wòlíì rẹ̀. 26 Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Lefi dúró pẹ̀ohun èlò orin Dafidi, àti àwọn àlùfáà pẹ̀ìpè wọn.

27 Hesekiah pa á láṣẹ láti ẹbọ sísun lórí pẹpẹ, ẹbọ sísun náà ti bẹ̀rẹ̀, orin Olúwa bẹ̀rẹ̀ pẹ̀ìpè àti pẹ̀ohun èlò orin Dafidi ọba Israẹli. 28 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà wólẹ̀ sìn, àwọn akọrin kọrin, àwọn afùnpè fọn ìpè, gbogbo wọ̀nyí bẹ́̀ títí ẹbọ sísun náà fi parí tán.

29 Nígbà wọ́n ṣe ìparí ẹbọ rírú, ọba àti gbogbo àwọn ó pẹ̀rẹ̀ tẹ ara wọn ba, wọ́n sìn. 30 Pẹ̀lúpẹ̀Hesekiah ọba, àti àwọn ìjòyè pàṣẹ fún àwọn ọmọ Lefi, láti fi ̀rọ̀ Dafidi àti ti Asafu aríran, kọrin ìyìn Olúwa: wọ́n fi inú dídùn kọrin ìyìn, wọ́n tẹrí wọn ba, wọ́n sìn.

Ìrúbọ nínú tẹmpili

31 Nígbà náà ni Hesekiah dáhùn, ó , nísinsin yìí, ọwọ́ yín kún fún ̀bùn fún Olúwa, súnmọ́ ìhín, ẹbọ àti ọrẹ-ọpẹ́ sínú ilé Olúwa. Ìjọ ènìyàn ẹbọ àti ọrẹ-ọpẹ́ ; àti olúkúlùkù ọkàn rẹ̀ fẹ́, ẹbọ sísun .

32 Iye ẹbọ sísun, ìjọ ènìyàn , jẹ́ àádọ́rin akọ màlúù, àti ọgọ́rùn-ún àgbò, àti igba ̀dọ́-àgùntàn, gbogbo wọ̀nyí ni fún ẹbọ sísun Olúwa. 33 Àwọn ohun ìyàsímímọ́ jẹ́ ẹgbẹ̀ta (600) màlúù, àti ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) àgùntàn. 34 Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà pọ̀ , wọn le gbogbo àwọn ẹran ẹbọ sísun náà: nítorí náà àwọn arákùnrin wọn, àwọn Lefi ràn wọ́n lọ́wọ́, títí iṣẹ́ náà fi parí, àti títí àwọn àlùfáà ìyókù fi wọ́n mímọ́: nítorí àwọn ọmọ Lefi ṣe olóòtítọ́ ọkàn ju àwọn àlùfáà lọ láti ya ara wọn mímọ́. 35 Àti pẹ̀, àwọn ẹbọ sísun pàpọ̀, pẹ̀̀ẹbọ àlàáfíà, pẹ̀ẹbọ ohun mímu fún ẹbọ sísun.

Bẹ́̀ ni a tún bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìsìn ilé Olúwa. 36 Hesekiah yọ̀, àti gbogbo ènìyàn , Ọlọ́run ti múra àwọn ènìyàn náà sílẹ̀, nítorí lójijì ni a ṣe nǹkan náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também