Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 26

Ussiah ọba Juda

1 26.1-4: 2Ọb 14.21,22; 15.2,3. Nígbà náà gbogbo ènìyàn Juda Ussiah, ẹni ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínlógún wọ́n fi jẹ ọba ipò baba rẹ̀ Amasiah. 2 Òun ni ẹni náà ó tún Elati kọ́, ó padà Juda lẹ́yìn ìgbà Amasiah ọba ti sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀.

3 Ussiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínlógún nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún méjìléláàádọ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Jekoliah; ó láti Jerusalẹmu. 4 Ó ṣe ohun ó tọ́ ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bi baba rẹ̀ Amasiah ti ṣe. 5 Ó Olúwa ọjọ́ Sekariah, ẹni ó òye nínú ìran Ọlọ́run. Níwọ́n ọjọ́ ó ojú Olúwa, Ọlọ́run fún un ohun rere.

6 Ó lọ ogun pẹ̀Filistini ó odi Gati lulẹ̀, Jabne àti Aṣdodu. Ó ìlú rẹ̀ ó ̀gbẹ́ Aṣdodu àti níbìkan láàrín àwọn ará Filistini. 7 Ọlọ́run ràn án lọ́wọ́ lórí àwọn ará Filistini àti Arabia ń gbé Gur-baali àti lórí àwọn ará Mehuni. 8 Àwọn ará Ammoni gbé ̀bùn fún Ussiah, orúkọ rẹ̀ tàn káàkiri títí ó fi àtiwọ Ejibiti, nítorí ó ti di alágbára ńlá.

9 Ussiah kọ́ ilé ìṣọ́ Jerusalẹmu níbi ẹnu-bodè igun, àti níbi ẹnu-bodè àfonífojì àti níbi ìṣẹ́po odi ó wọn le 10 Ó tún ilé ìṣọ́ aginjù kọ́, ó gbẹ́ kànga púpọ̀, nítorí ó ni ẹran ̀sìn púpọ̀ ilẹ̀ ìsàlẹ̀ àti pẹ̀tẹ́lẹ̀. Ó àwọn ènìyàn ń ṣiṣẹ́ pápá àti ọgbà àjàrà orí òkè ilẹ̀ ọlọ́ràá, nítorí ó fẹ́ràn àgbẹ̀ ṣíṣe.

11 Ussiah àwọn ẹgbẹ́ ogun wọ́n kọ́ dáradára, wọ́n múra tán láti lọ pẹ̀ẹgbẹgbẹ́ gẹ́gẹ́ iye kíkà wọn gẹ́gẹ́ ọwọ́ Jeieli akọ̀àti Maaseiah ìjòyè lábẹ́ ọwọ́ Hananiah, ̀kan lára àwọn olórí ogun ọba. 12 Àpapọ̀ iye olórí àwọn alágbára akọni ogun jẹ́ ẹgbẹ̀tàlá (2,600). 13 Lábẹ́ olórí àti olùdarí wọn, wọ́n jẹ́ alágbára akọni ogun ̀kẹ́ mẹ́̀́dógún ó ̀́dẹ́gbàárin (307,500), ó ti múra fún ogun ńlá náà, àti alágbára ńlá jagunjagun kan láti ran ọba lọ́wọ́ ̀rẹ̀. 14 Ussiah pèsè ̀kọ̀, asà, akọ́rọ́, àti ohun èlò ìhámọ́ra ọrun títí òkúta kànnàkànnà fún ọwọ́ àwọn ọmọ-ogun. 15 Jerusalẹmu ó ṣe ohun ̀rọ ìjagun, iṣẹ́ ọwọ́ ọlọ́gbọ́n ènìyàn, láti lórí ilé ìṣọ́ àti lórí igun odi láti fi tafà àti láti fi sọ òkúta ńlá. Orúkọ rẹ̀ tàn káàkiri, nítorí a ṣe ìrànlọ́wọ́ ìyanu fún un títí ó fi di alágbára.

16 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà Ussiah jẹ́ alágbára tán, ìgbéraga rẹ̀ gbé e ṣubú. Ó di aláìṣòótọ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. Ó wọ ilé Olúwa láti sun tùràrí lórí pẹpẹ tùràrí. 17 Asariah àlùfáà pẹ̀àwọn ọgọ́rin alágbára àlùfáà Olúwa mìíràn tẹ̀e. 18 Wọ́n takò ọba Ussiah, wọn , "dára fún , Ussiah, láti sun tùràrí Olúwa. Èyí fún àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Aaroni, ẹni ó ti mímọ́ láti sun tùràrí. Fi ibi mímọ́ sílẹ̀, nítorí ìwọ ti jẹ́ aláìṣòótọ́, ìwọ jẹ́ ẹni ọlá láti ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run."

19 Ussiah, ẹni ó àwo tùràrí ọwọ́ rẹ̀ ṣetán láti sun tùràrí bínú. Nígbà ó ń bínú àwọn àlùfáà níwájú wọn, níwájú pẹpẹ tùràrí ilé Olúwa, ̀tẹ̀ yọ jáde iwájú orí rẹ̀. 20 26.20-23: 2Ọb 15.5-7.Nígbà Asariah olórí àlùfáà àti gbogbo àwọn àlùfáà yòókù ó, wọ́n i ó ̀tẹ̀ níwájú orí rẹ̀, bẹ́̀ ni wọ́n sáré gbé e jáde pẹ̀lúpẹ̀, òun tìkára rẹ̀ ti fẹ́ láti jáde, nítorí Olúwa ti kọlù ú.

21 Ọba Ussiah ̀tẹ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀. Ó gbé ilé àwọn adẹ́tẹ̀, a e kúrò ilé Olúwa. Jotamu ọmọ rẹ̀ gba ipò rẹ̀, ó ń ṣe ìdájọ́ lórí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà.

22 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Ussiah láti ìbẹ̀rẹ̀ títí òpin, ni a kọ láti ọwọ́ wòlíì Isaiah ọmọ Amosi. 23 Ussiah sùn pẹ̀àwọn baba, rẹ̀ a sin ̀gbẹ́ wọn nínú oko ìsìnkú fún ti iṣẹ́ àwọn ọba, nítorí àwọn ènìyàn "Ó ààrùn ̀tẹ̀," Jotamu ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também