Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 30

Hesekiah ṣe àsè ìrékọjá

1 Hesekiah ránṣẹ́ gbogbo Israẹli àti Juda, ó kọ ìwé Efraimu àti Manase, wọn ó sínú ilé Olúwa Jerusalẹmu láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. 2 Nítorí ọba ti gbìmọ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àti gbogbo ìjọ ènìyàn Jerusalẹmu, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ oṣù kejì. 3 Nítorí wọn pa á mọ́ àkókò náà, nítorí àwọn àlùfáà i ya ara wọn mímọ́ ; bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn ì ara wọn jọ Jerusalẹmu. 4 ̀rọ̀ náà tọ́ lójú ọba àti lójú gbogbo ìjọ ènìyàn. 5 Bẹ́̀ ni wọ́n fi àṣẹ kan lélẹ̀, láti kéde gbogbo Israẹli láti Beerṣeba àní títí Dani, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli Jerusalẹmu: nítorí wọn pa á mọ́ ọjọ́ púpọ̀ gẹ́gẹ́ a ti kọ ́.

6 Bẹ́̀ àwọn oníṣẹ́ ń sáré lọ pẹ̀ìwé láti ọwọ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbogbo Israẹli àti Juda; àti gẹ́gẹ́ àṣẹ ọba, ,

"̀yin ọmọ Israẹli padà Olúwa Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki, àti Israẹli, òun ó yípadà àwọn ìyókù nínú yín, ó sálà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria. 7 ̀yin ó ṣe dàbí àwọn baba yín, àti àwọn arákùnrin yín ó dẹ́ṣẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn, nítorí náà ó ṣe fi wọ́n fún ìdahoro ̀yin ti . 8 Ǹjẹ́ ̀yin ó ṣe ṣe ọlọ́rùn líle, àwọn baba yín, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ ara yín lọ́wọ́ fún Olúwa, wọ inú ibi mímọ́ rẹ̀ lọ, ti òun ti ìyàsímímọ́ títí láé. sin Olúwa, Ọlọ́run yín gbígbóná ìbínú rẹ̀ ó yípadà kúrò ̀dọ̀ yín. 9 Nítorí ̀yin tún yípadà Olúwa, àwọn arákùnrin yín, àti àwọn ọmọ yín, yóò àánú níwájú àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ, wọn ó tún padà ilẹ̀ : nítorí Olúwa Ọlọ́run yín, oníyọnu àti aláàánú ni, yóò ojú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ yín, ̀yin padà sọ́dọ̀ rẹ̀."

10 Bẹ́̀ ni àwọn oníṣẹ́ náà kọjá láti ìlú ìlú, ilẹ̀ Efraimu àti Manase títí Sebuluni, ṣùgbọ́n wọ́n fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́, wọ́n gàn wọ́n. 11 Síbẹ̀ òmíràn nínú àwọn ènìyàn Aṣeri àti Manase àti Sebuluni rẹ̀ ara wọn sílẹ̀, wọ́n Jerusalẹmu. 12 Juda pẹ̀, ọwọ́ Ọlọ́run láti fún wọn ọkàn kan láti pa òfin ọba mọ́ àti àwọn ìjòyè, nípa ̀rọ̀ Olúwa.

13 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ Jerusalẹmu, láti pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ oṣù kejì. 14 Wọ́n dìde, wọ́n gbogbo pẹpẹ ó Jerusalẹmu lọ, àti gbogbo pẹpẹ tùràrí ni wọ́n lọ, wọ́n wọ́n odò Kidironi.

15 Nígbà náà ni wọ́n pa ẹran ìrékọjá náà ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì: ojú ti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, wọ́n ara wọn mímọ́, wọ́n ẹbọ sísun sínú ilé Olúwa. 16 Wọ́n dúró ipò wọn, ètò wọn gẹ́gẹ́ òfin Mose, ènìyàn Ọlọ́run: àwọn àlùfáà wọ́n ̀jẹ̀ náà, wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi. 17 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó nínú ìjọ ènìyàn náà ara wọn mímọ́: nítorí náà ni àwọn ọmọ Lefi ṣe ń tọ́àti pa ẹran ìrékọjá fún olúkúlùkù ẹni ó ṣe aláìmọ́, láti á mímọ́ Olúwa. 18 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní ̀pọ̀lọpọ̀ nínú Efraimu àti Manase, Isakari, àti Sebuluni wẹ̀ ara wọn mọ́ síbẹ̀ wọ́n jẹ ìrékọjá náà, í ṣe gẹ́gẹ́ a ti kọ ́. Ṣùgbọ́n Hesekiah bẹ̀bẹ̀ fún wọn, , Olúwa, ẹni rere, dáríjì olúkúlùkù, 19 ó múra ọkàn rẹ̀ láti Ọlọ́run, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀ ṣùgbọ́n í ṣe nípa ìwẹ̀nùmọ́ mímọ́ 20 Olúwa gbọ́ ti Hesekiah, ó àwọn ènìyàn náà láradá.

21 Àwọn ọmọ Israẹli a Jerusalẹmu fi ayọ̀ ńlá pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ ọjọ́ méje: àwọn ọmọ Lefi, àti àwọn àlùfáà yin Olúwa lójoojúmọ́, wọ́n ń fi ohun èlò olóhùn gooro kọrin Olúwa.

22 Hesekiah sọ̀rọ̀ ìtùnú fún gbogbo àwọn ọmọ Lefi, ó lóye ìmọ̀ rere Olúwa: ọjọ́ méje ni wọ́n fi jẹ àsè náà wọ́n ẹbọ àlàáfíà, wọ́n ń fi ohùn rara dúpẹ́ fún Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn.

23 Gbogbo ìjọ náà gbìmọ̀ láti pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́: wọ́n fi ayọ̀ pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́. 24 Nítorí Hesekiah, ọba Juda, ta ìjọ ènìyàn náà ọrẹ, ẹgbẹ̀rún (1,000) akọ màlúù, àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn. ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn àlùfáà ya ara wọn mímọ́. 25 Gbogbo ìjọ ènìyàn Juda pẹ̀àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó ti inú Israẹli jáde , àti àwọn àjèjì ó ti ilẹ̀ Israẹli jáde , àti àwọn ń gbé Juda yọ̀. 26 Bẹ́̀ ni ayọ̀ ńlá Jerusalẹmu: nítorí láti ọjọ́ Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli, irú èyí Jerusalẹmu. 27 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi dìde, wọ́n súre fún àwọn ènìyàn náà: a gbọ́ ohùn wọn, àdúrà wọn gòkè lọ si ibùgbé mímọ́ rẹ̀, àní ̀run.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também