Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 25

Amasiah ọba Juda

1 25.1-4: 2Ọb 14.2-6. Amasiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani, ó láti Jerusalẹmu. 2 Ó ṣe ohun ó dára lójú Olúwa, ṣùgbọ́n í ṣe tọkàntọkàn. 3 Lẹ́yìn ìjọba ti ìdarí rẹ̀, ó pa àwọn oníṣẹ́ ó pa baba rẹ̀ ọba. 4 Síbẹ̀ pa àwọn ọmọ wọn, ṣùgbọ́n ó ṣe ìbámu pẹ̀ohun a kọ nínú òfin nínú ìwé Mose, níbi Olúwa ti paláṣẹ , "A gbọdọ̀ pa àwọn baba fún àwọn ọmọ wọn tàbí àwọn ọmọ fún baba wọn, olúkúlùkù ni ó fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀."

5 Amasiah, pe gbogbo àwọn ènìyàn Juda pọ̀, ó fi iṣẹ́ wọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ ìdílé wọn àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ̀rọ̀̀rún fún gbogbo Juda àti Benjamini, ó gbá iye wọn láti ẹni ogún ọdún àti bẹ́̀ lọ jọ, ó i ̀kẹ́ mẹ́̀́dógún (300,000) àwọn ọkùnrin ni ó ti múra fún ìsìn ogun, ó gbá ̀kọ̀ àti àpáta . 6 Ó ̀kẹ́ márùn-ún (100,000) àwọn ọkùnrin oníjà láti Israẹli fún ọgọ́rùn-ún àwọn tálẹ́ǹtì fàdákà.

7 Ṣùgbọ́n ènìyàn Ọlọ́run kan tọ̀ ́ ó , "Ọba, àwọn ̀wọ́ ogun láti Israẹli gbọdọ̀ yan pẹ̀rẹ, nítorí Olúwa pẹ̀Israẹli í ṣe pẹ̀ẹnìkankan láti Efraimu. 8 Àní, lọ pẹ̀ìmúláyàle ojú ogun, Ọlọ́run yóò ́ ṣubú níwájú àwọn ̀, nítorí Ọlọ́run agbára láti ràn ́ lọ́wọ́ àti láti ́ ṣubú."

9 Amasiah bi ènìyàn Ọlọ́run , "Ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì mo ti san fún àwọn ̀wọ́ ogun àwọn ọmọ Israẹli ń kọ́?"

Ènìyàn Ọlọ́run dáhùn "Olúwa fún èyí ó ju ìyẹn lọ."

10 Bẹ́̀ ni Amasiah, àwọn ọwọ́ ogun ó ti ̀dọ̀ rẹ̀ láti Efraimu . Ó rán wọn lọ ilé. Wọ́n kún fún ìbínú pẹ̀Juda, wọ́n padà lọ ilé pẹ̀ìbínú ńlá.

11 25.11: 2Ọb 14.7. Nígbà náà, Amasiah ko ogun rẹ jọ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ lọ àfonífojì iyọ̀, níbi ó ti pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) àwọn ọkùnrin Seiri. 12 Àwọn ọkùnrin Juda pẹ̀fi agbára àwọn ọkùnrin ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) láààyè. Wọ́n wọn lọ orí òkè bèbè òkúta, wọ́n wọ́n sílẹ̀, gbogbo wọn fọ́ wẹ́wẹ́.

13 báyìí àwọn ̀wọ́ ogun Amasiah ti rán lọ padà, wọn nípa nínú ogun gbógun àwọn ìlú Juda láti Samaria Beti-Horoni. Wọ́n pa ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) nínú wọn, wọ́n ̀pọ̀ ìkógun ńlá.

14 Nígbà Amasiah padà láti ibi pípa àwọn ará Edomu, ó àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn Seiri padà . Ó gbé wọn kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àwọn ọlọ́run tirẹ̀. Ó tẹríba fún wọn, ó ẹbọ fún wọn. 15 Ìbínú Olúwa ru Amasiah, ó rán wòlíì kan i, ó , "ni ó ìwọ fi ń béèrè lọ́wọ́ àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn yìí, wọn le gba àwọn ènìyàn tiwọn kúrò lọ́wọ́ rẹ?"

16 ó ti n sọ̀rọ̀, ọba fún un , "Ṣé a yàn ́ olùgba ọba lámọ̀ràn ni? Dúró! Èéṣe a ó fi ́ bolẹ̀?"

Bẹ́̀ ni, wòlíì náà dúró ṣùgbọ́n ó , "Èmi mọ̀ Ọlọ́run ti pinnu láti pa ́ run nítorí ìwọ ti ṣe èyí, ìwọ tẹ́ìmọ̀ràn mi."

17 25.17-20,21-24: 2Ọb 14.8-14. Lẹ́yìn Amasiah ọba Juda ti béèrè lọ́wọ́ àwọn olùdámọ̀ràn, ó rán ìpèníjà yìí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu, ọba Israẹli , "mi lójúkojú."

18 Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì padà Amasiah ọba Juda , "Koríko kékeré kan Lebanoni rán iṣẹ́ igi kedari Lebanoni, fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ìgbéyàwó. Nígbà náà, ẹhànnà ẹranko ènìyàn ni Lebanoni , ó tẹ òṣùṣú náà lábẹ́ ẹsẹ̀. 19 Ìwọ fún ara à rẹ , ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu àti nísinsin yìí ìwọ ìhàlẹ̀ àti ìgbéraga. Ṣùgbọ́n dúró ilé! ni ó ìwọ fi ń wàhálà o fi ń fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀?"

20 Amasiah, ó ó tẹ́nítorí Ọlọ́run ṣe é ó gbé wọn Jehoaṣi lọ́wọ́: nítorí wọ́n àwọn ọlọ́run Edomu. 21 Bẹ́̀ ni Jehoaṣi, ọba Israẹli: òun àti Amasiah ọba Juda dojúkọ ara wọn Beti-Ṣemeṣi Juda. 22 Àwọn ọmọ Israẹli da Juda , gbogbo olúkúlùkù ènìyàn sálọ ìlú rẹ̀. 23 Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára Amasiah ọba Juda, ọmọ Joaṣi ọmọ Ahasiah Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà Joaṣi u Jerusalẹmu. Ó ògiri Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ẹnu-ọ̀Efraimu igun ẹnu-ọ̀apá kan títí ń lọ irinwó (400) ìgbọ̀nwọ́ gígùn. 24 Ọba gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun èlò wọ́n ni ilé Ọlọ́run ́ àbojútó Obedi-Edomu, lápapọ̀ pẹ̀àwọn ìṣúra ààfin àti àwọn ògo pẹ̀, ó padà lọ Samaria.

25 25.25-28: 2Ọb 14.17-20. Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́̀́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli. 26 Fún ti iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Amasiah láti ìbẹ̀rẹ̀ ìparí, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé àwọn ọba Juda àti Israẹli? 27 Láti ìgbà Amasiah ti yípadà kúrò láti máa tẹ̀Olúwa, wọ́n dìtẹ̀ i Jerusalẹmu, ó sálọ Lakiṣi ṣùgbọ́n, wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀e lọ Lakiṣi, wọ́n pa á síbẹ̀. 28 A gbé e padà pẹ̀ẹṣin. A sin ín pẹ̀àwọn baba rẹ̀ ìlú ńlá ti Juda.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também