Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 10

Israẹli ṣọ̀tẹ̀ lórí Rehoboamu

1 10.1-19: 1Ọb 12.1-19. Rehoboamu lọ Ṣekemu nítorí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti lọ síbẹ̀ láti fi jẹ ọba. 2 Nígbà Jeroboamu ọmọ Nebati gbọ́ ẹni ti ó Ejibiti, níbi ó ti kúrò lọ́dọ̀ ọba Solomoni ó padà láti Ejibiti. 3 Bẹ́̀ ni nígbà náà ó ránṣẹ́ Jeroboamu àti òun àti gbogbo àwọn Israẹli lọ ̀dọ̀ Rehoboamu wọ́n fún , 4 "Baba rẹ gbé àjàgà ó wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ un fúyẹ́, iṣẹ́ líle àti àjàgà wúwo ó gbé ka orí wa, àwa yóò sìn ́."

5 Rehoboamu dáhùn , "padà sọ́dọ̀ mi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta." Bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn náà lọ.

6 Nígbà náà ni ọba Rehoboamu fi ̀ràn lọ̀ àwọn àgbàgbà ó ti ń sin baba rẹ̀ Solomoni nígbà ayé rẹ̀, ó bi wọ́n léèrè pe, "Báwo ni ̀yin yóò ṣe gbà ìmọ̀ràn láti àwọn ènìyàn wọ̀nyí lóhùn?"

7 Wọ́n dáhùn, "ìwọ yóò ṣe rere àwọn ènìyàn wọ̀nyí o ṣe ìre fún wọn, o fún wọn ìdáhùn rere, wọn yóò máa jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nígbà gbogbo."

8 Ṣùgbọ́n Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn náà àwọn àgbàgbà fi fún un, ó fi ̀rọ̀ lọ àwọn ọmọ ọkùnrin ó ti dàgbàsókè pẹ̀rẹ̀ wọ́n ń dúró níwájú rẹ̀. 9 Ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni ìmọ̀ràn yín? Báwo ni a ṣe àwọn ènìyàn wọ̀nyí wọ́n fún mi , àjàgà baba rẹ gbé wa ó fúyẹ́ díẹ̀.’ "

10 Àwọn ̀dọ́mọdé ó ti dàgbà pẹ̀rẹ a lóhùn , "Sọ fún àwọn ènìyàn ó fún , Baba rẹ gbé àjàgà wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n àjàgà wa fúyẹ́,’ fún wọn , Ìka ọwọ́ mi kékeré, ó nípọn ju ìbàdí baba mi lọ. 11 Baba mi gbé àjàgà wúwo ka orí yín; èmi yóò tún ó wúwo í. Baba mi fi pàṣán yín; èmi yóò yín pẹ̀àkéekèe.’ "

12 ọjọ́ kẹta Jeroboamu àti gbogbo ènìyàn padà ̀dọ̀ Rehoboamu, gẹ́gẹ́ ọba ti sọ, "padà sọ́dọ̀ mi ọjọ́ kẹta." 13 Nígbà náà ni ọba wọn lóhùn ̀líle. Rehoboamu ọba kọ̀ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà sílẹ̀, 14 Ó tẹ̀ìmọ̀ràn àwọn ̀dọ́mọdé, ó , "Baba mi àjàgà yín wúwo; èmi yóò ó wúwo bẹ́̀ lọ. Baba mi yín pẹ̀pàṣán; èmi yóò yín pẹ̀àkéekèe." 15 Bẹ́̀ ni ọba fetísí àwọn ènìyàn, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni. Láti ̀rọ̀ Olúwa ṣẹ a ti sọ fún Jeroboamu ọmọ Nebati nípasẹ̀ Ahijah ará Ṣilo.

16 Nígbà gbogbo Israẹli i ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn, wọ́n ọba lóhùn ,

"Ìpín a nínú Dafidi,

ìní wo ni a nínú ọmọ Jese?

lọ àgọ́ yín, ̀yin Israẹli!

Bojútó ilé rẹ, ìwọ Dafidi!"

Bẹ́̀ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọ ilé wọn. 17 Ṣùgbọ́n ti àwọn ọmọ Israẹli ń gbé ìlú Juda, Rehoboamu ń jẹ ọba lórí wọn.

18 Ọba Rehoboamu rán Adoniramu jáde, ẹni ó ìkáwọ́ iṣẹ́ onírúurú, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli sọ ́ òkúta pa. Ọba Rehoboamu, gbìyànjú láti inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó sálọ Jerusalẹmu. 19 Bẹ́̀ ni Israẹli ìṣọ̀tẹ̀ lórí ilé Dafidi títí fi di òní yìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também