Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 35

Josiah ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá

1 35.1-19: 2Ọb 23.21-23. Síwájú i, Josiah ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá Olúwa Jerusalẹmu, ̀dọ́-àgùntàn àjọ ìrékọjá náà ni wọ́n pa ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní. 2 Ó yàn àwọn àlùfáà iṣẹ́ wọn, ó gbà wọ́n ìyànjú ìsìn ilé Olúwa. 3 Ó fún àwọn ọmọ Lefi, ẹni ń kọ́ gbogbo àwọn Israẹli ẹni a ti mímọ́ fún Olúwa gbé àpótí ̀ìyàsọ́tọ̀ ilé Olúwa Solomoni ọmọ Dafidi ọba Israẹli ti kọ́. gbọdọ̀ jẹ́ ẹrù àgbéká èjìká rẹ̀. Nísinsin yìí sin Olúwa Ọlọ́run yín àti àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli. 4 múra sílẹ̀ nípa ìdílé ẹsẹẹsẹ yín gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ a kọ́ láti ọwọ́ Dafidi ọba Israẹli àti gẹ́gẹ́ ọmọ rẹ̀ Solomoni.

5 "Dúró ibi mímọ́ pẹ̀àkójọpọ̀ àwọn ọmọ Lefi fún ̀kọ̀̀kan ìpín àwọn ìdílé àwọn ẹgbẹ́ ará ìlú, àwọn ènìyàn ó dùbúlẹ̀. 6 pa ẹran àjọ ìrékọjá náà, ya ara yín sọ́tọ̀ pèsè ẹran fún àwọn ẹgbẹ́ arákùnrin yín, ṣe ohun Olúwa paláṣẹ láti ọwọ́ Mose."

7 Josiah pàṣẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn ó dùbúlẹ̀ ó níbẹ̀ iye rẹ̀ jẹ ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000) ̀dọ́-àgùntàn àti ọmọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ìrékọjá, àti pẹ̀ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) akọ màlúù, gbogbo wọ̀nyí jẹ́ ohun ìní láti ̀dọ̀ ọba.

8 Àwọn ìjòyè rẹ̀ fi tinútinú ta àwọn ènìyàn náà ọrẹ àti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Hilkiah, Sekariah àti Jehieli, àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run, fún àwọn àlùfáà ẹgbẹ̀tàlá (2,600) ẹbọ àjọ ìrékọjá àti ̀́dúnrún (300) ẹran ̀sìn. 9 Àti pẹ̀Konaniah àti pẹ̀Ṣemaiah àti Netaneli, àti àwọn arákùnrin rẹ̀, àti Haṣabiah, Jeieli àti Josabadi olórí àwọn ọmọ Lefi, ó pèsè ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ẹbọ ìrékọjá àti ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) orí ẹran ̀sìn fún àwọn ọmọ Lefi.

10 Nítorí náà, a múra ìsìn náà sílẹ̀, àwọn àlùfáà dúró ipò wọn pẹ̀àwọn ọmọ Lefi nípa iṣẹ́ wọn gẹ́gẹ́ ọba ti pa á láṣẹ. 11 ti àjọ ìrékọjá a pa ẹran, àwọn àlùfáà wọ́n ̀jẹ̀ náà wọ́n gbé ọwọ́ wọn, nígbà àwọn ọmọ Lefi bọ ẹranko. 12 Wọ́n ya àwọn ẹbọ sísun apá kan láti fi wọ́n fún gẹ́gẹ́ ìpín àwọn ìdílé àwọn ènìyàn láti ẹbọ Olúwa. Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ sínú ìwé Mose. Wọ́n ṣe bákan náà pẹ̀àwọn ẹran ̀sìn. 13 Wọ́n fi sun àjọ ìrékọjá lórí iná gẹ́gẹ́ ìlànà, wọ́n bọ ẹbọ mímọ́ nínú ìkòkò, nínú ọpọ́n àti nínú agbada, wọ́n pín wọn kíákíá fún gbogbo àwọn ènìyàn. 14 Lẹ́yìn èyí, wọ́n múra sílẹ̀ fún ara wọn àti fún àwọn àlùfáà nítorí àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Aaroni, ni wọ́n ẹbọ sísun àti ̀títí di àṣálẹ́. Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Lefi múra sílẹ̀ fún ara wọn àti fún àwọn ọmọ Aaroni àlùfáà.

15 Àwọn akọrin, àwọn ọmọ Asafu, ni wọ́n ipò wọn a paláṣẹ fún wọn láti ọwọ́ Dafidi, Asafu, Hemani àti Jedutuni àwọn aríran ọba àti àwọn olùṣọ́olúkúlùkù ẹnu-ọ̀gbọdọ̀ fi ojú ̀wọn sílẹ̀, nítorí àwọn ẹgbẹ́ ọmọ lefi ti múra sílẹ̀ fún wọn.

16 Bẹ́̀ ni àsìkò náà gbogbo àwọn ìsìn Olúwa ni wọ́n gbé jáde fún iṣẹ́ ìrántí àjọ ìrékọjá àti láti ẹbọ sísun lórí pẹpẹ Olúwa, gẹ́gẹ́ ọba Josiah ti pa á láṣẹ. 17 Àwọn ọmọ Israẹli ó gbé kalẹ̀ ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá àkókò náà àti àjọ àkàrà àìwú fún ọjọ́ méje. 18 Àjọ ìrékọjá náà ì èyí ó dàbí i rẹ̀ Israẹli títí ọjọ́ wòlíì Samuẹli, ̀kan lára àwọn ọba Israẹli ó pa irú àjọ ìrékọjá bẹ́̀ mọ́ gẹ́gẹ́ Josiah ti ṣe, pẹ̀àwọn àlùfáà àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo àwọn Juda àti Israẹli ó níbẹ̀ pẹ̀gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu. 19 Àjọ ìrékọjá yìí ni a ṣe ìrántí ọdún kejìdínlógún ìjọba Josiah.

Ikú Josiah

20 Lẹ́yìn gbogbo èyí nígbà Josiah ti tún ilẹ̀ náà ṣetán, Neko ọba Ejibiti gòkè lọ láti Karkemiṣi lórí odo Eufurate, Josiah jáde lọ láti pàdé rẹ̀ ibi ìjà. 21 Ṣùgbọ́n Neko rán ìránṣẹ́ i , "Ìjà wo ni ó ń bẹ láàrín èmi àti ìwọ, ọba Juda? í ṣe ìwọ ni èmi tọ̀ àkókò yìí, ṣùgbọ́n, ilé pẹ̀èyí ti mo níjà. Ọlọ́run ti sọ fún mi láti yára àti láti dúró nípa ṣíṣe ìdènà Ọlọ́run, ẹni ó pẹ̀mi, òun a pa ́ run."

22 Josiah, yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó pa ara rẹ̀ ó le a , fi etí ̀rọ̀ Neko láti ẹnu Ọlọ́run , ó jagun àfonífojì Megido.

23 Tafàtafà ta ọfà ọba Josiah, ó sọ fún àwọn ìjòyè , "gbé mi kúrò, èmi ti gba ọgbẹ́ gidigidi." 24 Bẹ́̀ ni wọ́n gbé e jáde kúrò nínú kẹ̀kẹ́ náà, wọ́n gbé e sínú kẹ̀kẹ́ mìíràn, wọ́n gbé e Jerusalẹmu, níbi ó ti , wọ́n sin ín sínú ̀kan nínú àwọn ibojì àwọn baba rẹ̀, gbogbo Juda àti gbogbo Jerusalẹmu ṣọ̀fọ̀ Josiah.

25 Jeremiah pohùnréré ẹkún fún Josiah, gbogbo àwọn akọrin ọkùnrin àti gbogbo àwọn akọrin obìnrin ń sọ ti Josiah nínú orin ẹkún wọn Israẹli títí di òní. Èyí di àṣà Jerusalẹmu, a kọ ́ sínú àwọn orin ẹkún.

26 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Josiah àti ìwà rere rẹ̀, gẹ́gẹ́ èyí a ti kọ sínú ìwé òfin Olúwa. 27 Gbogbo iṣẹ́ náà, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí òpin ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Israẹli àti Juda.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também