Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 18

Mikaiah sọtẹ́lẹ̀ lórí Ahabu

1 18.1-34: 1Ọb 22.1-35. Nísinsin yìí Jehoṣafati ọrọ̀ àti ọlá púpọ̀, ó àna pẹ̀Ahabu nípa fífẹ́ ọmọ rẹ̀. 2 Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, ó sọ̀kalẹ̀ láti lọ Ahabu lálejò Samaria. Ahabu pa àgùntàn àti màlúù púpọ̀ fún àti àwọn ènìyàn ó pẹ̀rẹ̀ ó rọ̀ ́ láti dojú ìjà kọ Ramoti Gileadi. 3 Ahabu ọba Israẹli béèrè lọ́wọ́ ọba Jehoṣafati, ọba Juda , "Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀mi Ramoti Gileadi?"

Jehoṣafati a lóhùn , "Èmi gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe , àti àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ ènìyàn rẹ àwa yóò pẹ̀rẹ nínú ogun náà". 4 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati náà tún fún ọba Israẹli , "Kọ́kọ́ béèrè lọ́wọ́ Olúwa."

5 Bẹ́̀ ọba Israẹli àwọn wòlíì papọ̀, irinwó (400) ọkùnrin ó bi wọ́n , "àwa lọ ogun Ramoti Gileadi tàbí èmi ó jọ̀wọ́ rẹ?"

Wọ́n dáhùn , "Lọ, nítorí Ọlọ́run yóò fi ọba lọ́wọ́."

6 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati béèrè , "Ṣé ha wòlíì Olúwa níbí ẹni àwa ìbá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?"

7 Ọba Israẹli Jehoṣafati lóhùn , "Ọkùnrin kan síbẹ̀ lọ́dọ̀ ẹni àwa ìbá tún béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ṣùgbọ́n èmi kórìíra rẹ̀ nítorí jẹ́ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun rere kan nípa mi ṣùgbọ́n ṣe ohun búburú, gbogbo ìgbà òun náà ni Mikaiah ọmọ Imla."

Jehoṣafati lóhùn , "Ọba gbọdọ̀ sọ bẹ́̀."

8 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli pe ̀kan lára àwọn ìjòyè ó , "Mikaiah ọmọ Imla ó yára ."

9 Wọ́n wọ aṣọ ìgúnwà wọn, ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda wọ́n jókòó sórí ìtẹ́ wọ́n ìta ẹnu-bodè Samaria, pẹ̀gbogbo àwọn wòlíì ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn. 10 Nísinsin yìí Sedekiah ọmọ Kenaana ti ṣe ìwo irin, ó , "Èyí ni ohun Olúwa sọ: Pẹ̀èyí ìwọ yóò kan àwọn ará Siria títí ìwọ ó fi pa wọ́n run.’ "

11 Gbogbo àwọn wòlíì ó ni wọn ń sọtẹ́lẹ̀ àkókò kan náà. Wọ́n , "Dojúkọ Ramoti Gileadi ìwọ yóò ṣẹ́gun, nítorí Olúwa yóò fi ọba lọ́wọ́."

12 Ìránṣẹ́ ó ti lọ pe Mikaiah fún un , "ó, gẹ́gẹ́ ọkùnrin kan àti òmíràn wòlíì fi ẹnu kan sọ rere fún ọba. Jẹ́ ̀rọ̀ rẹ ó dàbí ̀kan nínú tiwọn, o sọ rere."

13 Ṣùgbọ́n Mikaiah pe, "Gẹ́gẹ́ ó ti dájú Olúwa ń bẹ láààyè, èmi yóò sọ ohun Ọlọ́run mi sọ."

14 Nígbà ó , ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, "Mikaiah, ṣe àwa ki ó lọ ogun ti Ramoti Gileadi, tàbí àwa ó fàsẹ́yìn?"

Ó dáhùn , "dojúkọ wọ́n ṣẹ́gun, nítorí a ó fi wọ́n yín lọ́wọ́."

15 Ọba fún un , "Ìgbà mélòó ni èmi ó fi ́ búra láti sọ ohun kan fún mi ṣe ̀rọ̀ òtítọ́ orúkọ Olúwa?"

16 18.16: Nu 27.17; El 34.5; Mt 9.36; Mk 6.34. Mikaiah dáhùn , "Mo gbogbo Israẹli túká kiri lórí àwọn òkè àgùntàn olùṣọ́, Olúwa , Àwọn wọ̀nyí olúwa. Jẹ́ olúkúlùkù padà ilé rẹ̀ àlàáfíà.’ "

17 Ọba Israẹli fún Jehoṣafati , "Ṣe èmi sọ fún òun sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere kankan nípa mi , ṣùgbọ́n búburú nìkan?"

18 Mikaiah tẹ̀síwájú , "Nítorí náà, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, mo Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ gbogbo ogun ̀run dúró lápá ̀tún àti lápá òsì. 19 Olúwa , Ta ni yóò tan Ahabu ọba Israẹli lọ Ramoti Gileadi ó lọ ikú rẹ̀ níbẹ̀?’

"Èkínní sọ tìhín, òmíràn sọ tọ̀hún. 20 ìparí, ni ̀kan síwájú, ó dúró níwájú Olúwa ó , Èmi yóò tàn án.

" Nípa ̀wo?Olúwa béèrè.

21 " Èmi yóò lọ láti lọ di ̀èké ẹnu gbogbo àwọn wòlíì.

" Ìwọ yóò borí nínú ìtànjẹ rẹ̀ báyìí,ni Olúwa . Lọ ó ṣe bẹ́̀.’

22 "Bẹ́̀ ni nísinsin yìí Olúwa ti fi ̀èké ẹnu àwọn wòlíì rẹ. Olúwa ti sọ ibi ."

23 Nígbà náà Sedekiah ọmọ Kenaana lọ sókè ó gbá Mikaiah ojú. Ó béèrè , "̀wo ni ̀Olúwa gbà kọjá lọ kúrò lọ́dọ̀ mi láti sọ̀rọ̀?"

24 Mikaiah dáhùn , "Ìwọ yóò ṣe ìwádìí ọjọ́ ìwọ yóò pamọ́ sínú ìyẹ̀."

25 Ọba Israẹli pa á láṣẹ , "Mikaiah o ran padà Amoni olórí ìlú àti Joaṣi ọmọ ọba, 26 Ó , Èyí ni ohun ọba sọ, fi ènìyàn yìí sínú túbú ṣe fún un ohunkóhun ṣùgbọ́n àkàrà àti omi títí èmi yóò fi àlàáfíà.’ "

27 Mikaiah pe, "ìwọ padà àlàáfíà, Olúwa sọ̀rọ̀ láti ̀dọ̀ mi." Nígbà náà, ó fi kún un , "gbọ́ ̀rọ̀ mi, gbogbo ̀yin ènìyàn!"

A pa Ahabu Ramoti Gileadi

28 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda lọ sókè Ramoti Gileadi. 29 Ọba Israẹli sọ fún Jehoṣafati , "Èmi yóò lọ ojú ìjà, ṣùgbọ́n ìwọ wọ aṣọ ìgúnwà rẹ." Bẹ́̀ ni ọba Israẹli pa aṣọ rẹ̀ , ó lọ ojú ìjà.

30 Nísinsin yìí ọba Siria ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ ó ̀dọ̀ rẹ̀ , "ṣe pẹ̀ẹnìkankan, èwe tàbí àgbà àyàfi ọba Israẹli." 31 Nígbà àwọn olórí kẹ̀kẹ́ Jehoṣafati, wọ́n , "Èyí ọba Israẹli." Bẹ́̀ ni wọ́n yípadà láti a . Ṣùgbọ́n Jehoṣafati kégbe sókè, Olúwa ràn án lọ́wọ́. Ọlọ́run wọn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, 32 Ó ṣe, nígbà olórí kẹ̀kẹ́ i í ṣe ọba Israẹli, wọ́n dáwọ́ lílé rẹ̀ dúró.

33 Ṣùgbọ́n ẹnìkan fa ọrun rẹ̀ láì pète, ó ọba Israẹli láàrín ìpàdé ̀irin, ọba sọ fún olùtọ́kẹ̀kẹ́ rẹ̀ , "ọwọ́ rẹ padà, o jáde kúrò lójú ìjà. Nítorí èmi ti gbọgbẹ́." 34 ọjọ́ pípẹ́, ìjà náà ń pọ̀ i, ọba Israẹli dúró nínú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ kọjú àwọn ará Siria títí ó fi di àṣálẹ́. Lẹ́yìn náà àkókò ìwọ oòrùn, ó .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também