Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 6

1 6.1-39: 1Ọb 8.12-50. Nígbà náà ni Solomoni , "Olúwa ti sọ òun yóò máa gbé nínú òkùnkùn ó ṣú biribiri; 2 ṣùgbọ́n èmi ti kọ́ tẹmpili dáradára fún ibi ìwọ yóò máa gbé títí láé."

3 ìgbà gbogbo ìjọ Israẹli dúró níbẹ̀, ọba yíjú padà ó fi ìbùkún fún gbogbo wọn. 4 Nígbà náà ni ó :

"Ògo ni fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ó fi ọwọ́ rẹ̀ ohun ó fi ẹnu rẹ̀ sọ fún Dafidi baba mi ṣẹ. Nítorí ó , 5 Láti ọjọ́ èmi ti àwọn ènìyàn mi jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, èmi yan ìlú kan nínú gbogbo ̀Israẹli, láti kọ́ ilé, orúkọ mi ó níbẹ̀, bẹ́̀ ni èmi yan ẹnikẹ́ni láti jẹ́ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi. 6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi ti yan Jerusalẹmu, orúkọ mi le è níbẹ̀, èmi ti yan Dafidi láti jẹ ọba lórí Israẹli ènìyàn mi.

7 "Baba mi Dafidi ti ní-in lọ́kàn láti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, àní Ọlọ́run Israẹli. 8 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Dafidi baba mi , Nítorí ó ọkàn rẹ láti kọ́ tẹmpili yìí fún orúkọ mi, ìwọ ṣe ohun dáradára láti èyí ọkàn rẹ̀. 9 Ṣùgbọ́n síbẹ̀, ìwọ kọ́ ni yóò kọ́ tẹmpili náà, ṣe ọmọ rẹ, ẹni o jẹ́ ẹran-ara àti ̀jẹ̀ rẹ: òun ni yóò kọ́ tẹmpili fún orúkọ mi.

10 "Olúwa ti ìlérí rẹ̀ ṣẹ. Èmi ti dìde ipò Dafidi baba mi, a gbé mi ka ìtẹ́ Israẹli, gẹ́gẹ́ Olúwa ti ṣe ìlérí, èmi ti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 11 Níbẹ̀ ni èmi gbé àpótí ̀Olúwa , nínú èyí ti májẹ̀ti Olúwa àwọn Israẹli ènìyàn mi ."

Solomoni gba àdúrà ìyàsímímọ́

12 Nígbà náà ni Solomoni dúró níwájú pẹpẹ Olúwa, iwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì. 13 Solomoni ṣe àga idẹ kan ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta gíga, a gbé e àárín àgbàlá ti òde. Ó dúró orí rẹ̀, àti ó kúnlẹ̀ lórí eékún rẹ̀ níwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì òkè ̀run. 14 Ó :

"Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, Ọlọ́run ó dàbí rẹ ̀run àti ayé: ìwọ o pa májẹ̀ìfẹ́ rẹ mọ́ pẹ̀àwọn ìránṣẹ́ rẹ ń fi tọkàntọkàn wọn rìn ̀rẹ. 15 Ìwọ o pa ìlérí o ṣe pẹ̀ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi mọ́; nítorí ìwọ ti fi ẹnu rẹ ṣe ìlérí àti ìwọ ti fi ọwọ́ rẹ un ṣẹ; ó ti lónìí yìí.

16 "Nísinsin yìí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pa ìlérí ó ti ṣe mọ́ fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi nígbà o , Ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ láti ọkùnrin láti jókòó níwájú mi lórí ìtẹ́ Israẹli, kìkì àwọn ọmọ rẹ wọ́n kíyèsi ara nínú gbogbo ohun wọ́n ṣe láti rìn níwájú mi gẹ́gẹ́ òfin mi gẹ́gẹ́ o ti ṣe.17 Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run Israẹli, jẹ́ ̀rọ̀ rẹ o ti ṣèlérí fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi ó ìmúṣẹ.

18 "Ṣùgbọ́n ṣé Ọlọ́run nítòótọ́ yóò máa àwọn ènìyàn gbé lórí ilẹ̀ ayé ? ̀run àti ̀run gíga le gbà ́. Báwo ni ó ṣe kéré , ilé Olúwa mo ti kọ́! 19 Síbẹ̀ ṣe àfiyèsí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ àti ̀bẹ̀ rẹ̀ fún àánú, Olúwa Ọlọ́run mi, gbọ́ ẹkún àti àdúrà ìránṣẹ́ rẹ̀ ń gbà níwájú rẹ. 20 ojú rẹ ó ṣí ilé Olúwa ̀sán àti lóru, ibí yìí ìwọ ti ìwọ yóò fi orúkọ rẹ síbẹ̀. ìwọ ó gbọ́ àdúrà ìránṣẹ́ rẹ ń gbà lórí ibí yìí. 21 Gbọ́ ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ àti ti àwọn ènìyàn Israẹli nígbà wọ́n ń gbàdúrà lórí ibí yìí. Gbọ́ láti ̀run, ibùgbé rẹ, nígbà ìwọ gbọ́, dáríjì.

22 "Nígbà ọkùnrin kan dẹ́ṣẹ̀ ẹnìkejì rẹ̀, a búra, ó búra níwájú pẹpẹ rẹ nínú ilé yìí, 23 nígbà náà, gbọ́ láti ̀run o dáhùn. Ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn ìránṣẹ́ rẹ, san padà fún ẹni ó jẹ̀bi nípa mímú padà orí òun tìkára rẹ̀ ohun ó ti ṣe. Ṣe ìdáláre fún olódodo, bẹ́̀ ni, fi fún un gẹ́gẹ́ òdodo rẹ̀.

24 "Nígbà àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ìjákulẹ̀ níwájú àwọn ̀nítorí wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀ àti nígbà wọ́n yípadà, wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, wọ́n gbàdúrà, wọ́n bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ nínú ilé Olúwa yìí, 25 nígbà náà, ni o gbọ́ láti ̀run o dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn Israẹli wọ́n o wọn padà sílé o ti fi fún wọn àti àwọn baba wọn.

26 "Nígbà a ti ̀run, òjò nítorí àwọn ènìyàn rẹ ti dẹ́ṣẹ̀ , nígbà wọ́n gbàdúrà ibí yìí wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ wọ́n yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ wọn nítorí ìwọ ti pọ́n wọn lójú, 27 nígbà náà gbọ́ láti ̀run o dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli kọ́ wọn ̀ó tọ́ nínú èyí wọn ó máa rìn, o rọ òjò sórí ilẹ̀ o ti fi fún àwọn ènìyàn rẹ fún ìní.

28 "Nígbà ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn ilẹ̀ náà, ìrẹ̀dànù tàbí ìmúwòdù, eṣú tàbí ẹlẹ́ǹgà, tàbí nígbà àwọn ̀wọn yọ wọ́n lẹ́nu nínú ̀kan lára àwọn ìlú wọn, ohunkóhun, ìpọ́njú tàbí ààrùn . 29 Nígbà àdúrà tàbí ̀bẹ̀ láti ̀dọ̀ ẹnikẹ́ni àwọn ènìyàn rẹ Israẹli olúkúlùkù mọ̀ nípa ìpọ́njú rẹ̀ àti ìbànújẹ́, ó tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì ìhà ilé Olúwa yìí. 30 Nígbà náà gbọ́ láti ̀run ibùgbé rẹ dáríjì, o pín fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́ i gbogbo ohun ó ṣe, nígbà ìwọ ti mọ ọkàn rẹ̀ (nítorí ìwọ nìkan ni ó mọ ọkàn ènìyàn.) 31 Bẹ́̀ ni wọn ó bẹ̀rẹ wọn ó rìn ̀rẹ gbogbo ìgbà wọ́n ń gbé nínú ilé o ti fi fún àwọn baba wa.

32 "ti àwọn àlejò wọn lára àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ṣùgbọ́n wọ́n láti ̀jíjìn nítorí orúkọ ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ àti nínà apá rẹ, nígbà ó ó gbàdúrà pẹ̀kíkojú si ilé Olúwa yìí. 33 Nígbà náà, gbọ́ láti ̀run àní láti ibi ibùgbé rẹ, o ṣe ohun àwọn àlejò béèrè lọ́wọ́ rẹ. Bẹ́̀ ni gbogbo àwọn ènìyàn ayé wọn mọ orúkọ rẹ wọn bẹ̀rẹ, gẹ́gẹ́ Israẹli ènìyàn rẹ ti ṣe, wọn ó mọ̀ ilé yìí èmi ti kọ, orúkọ rẹ ni ó ń jẹ́.

34 "Nígbà àwọn ènìyàn rẹ lọ sójú ogun lórí àwọn ̀wọn, nígbàkígbà o rán wọn, wọ́n gbàdúrà si ìhà ìlú yìí ìwọ ti yàn àti ilé Olúwa èmi ti kọ́ fún orúkọ rẹ. 35 Nígbà náà gbọ́ àdúrà wọn àti ̀bẹ̀ wọn láti ̀run, o ̀rọ̀ wọn dúró.

36 "Nígbà wọ́n dẹ́ṣẹ̀ nítorí ènìyàn kan í dẹ́ṣẹ̀—o bínú wọn o fi wọ́n fún àwọn ̀, wọ́n wọn ìgbèkùn ilẹ̀ ó jìnnà réré tàbí nítòsí, 37 ṣùgbọ́n, nígbà wọ́n ọkàn wọn padà ilẹ̀ wọ́n ti wọn ìgbèkùn, wọ́n ronúpìwàdà wọ́n bẹ̀bẹ̀ pẹ̀rẹ ilẹ̀ ìgbèkùn, wọn ó , Àwa ti dẹ́ṣẹ̀, àwa ti ṣe ohun dára, a ti ṣe búburú; 38 wọn yípadà pẹ̀gbogbo ọkàn àti ̀ilẹ̀ ìgbèkùn wọn níbi wọ́n ti wọn, wọ́n gbàdúrà wọn, kojú si ìlú ìwọ ti yàn àti lórí ilé Olúwa mo ti kọ́ fún orúkọ rẹ; 39 nígbà náà, láti ̀run, ibi ibùgbé rẹ, gbọ́ àdúrà wọn àti ̀bẹ̀ wọn, o ̀ràn wọn dúró, o dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn wọn, wọn ti dẹ́ṣẹ̀ .

40 "Nísinsin yìí, Ọlọ́run mi, jẹ́ ojú rẹ ó ṣí o tẹ́ etí rẹ sílẹ̀ fún àdúrà ibí yìí.

41 6.41-42: Sm 132.8-10. "Ǹjẹ́ nísinsin yìí dìde, Olúwa Ọlọ́run mi, ibi ìsinmi rẹ,

ìwọ àti àpótí ̀agbára rẹ.

Jẹ́ àwọn àlùfáà, Olúwa Ọlọ́run mi, o wọ̀ wọ́n láṣọ pẹ̀ìgbàlà,

jẹ́ àwọn àyànfẹ́ inú wọn ó dùn nínú ilé rẹ.

42 Olúwa Ọlọ́run mi, ṣe kọ̀ ẹni àmì òróró rẹ.

Rántí ìfẹ́ ńlá ó ṣe ìlérí fún Dafidi ìránṣẹ́ rẹ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também