Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 12

Ṣiṣaki gbógun ti Jerusalẹmu

1 12.1-16: 1Ọb 14.25-31. Lẹ́yìn ìgbà a fi ìjọba Rehoboamu múlẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba, ó ti di alágbára, òun àti gbogbo Israẹli, pẹ̀rẹ̀ ni wọ́n pa òfin Olúwa . 2 Nítorí wọn ṣọ òtítọ́ Olúwa. Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu ọdún karùn-ún ti ọba Rehoboamu. 3 Pẹ̀ẹgbàá mẹ́(12,000) kẹ̀kẹ́ àti ̀kẹ́ mẹ́ta (60,000) àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin àti àìníye ̀wọ́ ogun ti Libia, Sukki àti Kuṣi, ó pẹ̀rẹ̀ láti Ejibiti. 4 Ó fi agbára àwọn ìlú ààbò ti Juda, pẹ̀Jerusalẹmu ó ti jìnnà .

5 Nígbà náà, wòlíì Ṣemaiah ̀dọ̀ Rehoboamu àti ̀dọ̀ àwọn olórí Juda wọ́n ti péjọ Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀Ṣiṣaki, ó fún wọn , "Èyí ni ohun Olúwa : ìwọ ti pa ; nítorí náà èmi náà ti pa yín ̀dọ̀ Ṣiṣaki."

6 Àwọn olórí Israẹli àti ọba rẹ̀ ará wọn sílẹ̀, wọ́n , "Olódodo ni Olúwa."

7 Nígbà Olúwa i , wọ́n ti rẹ̀ ara wọn sílẹ̀ ̀rọ̀ Olúwa tọ Ṣemaiah lọ , "Níwọ́n ìgbà wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, Èmi yóò pa wọ́n ṣùgbọ́n, yóò fún wọn ìtúsílẹ̀ . Ìbínú mi yóò sórí Jerusalẹmu ipasẹ̀ Ṣiṣaki. 8 ó ti ó , wọn yóò sìn abẹ́ rẹ̀, wọn ó mọ̀ ìyàtọ̀ láàrín sìn àti sin àwọn ọba ilẹ̀ mìíràn."

9 Nígbà Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu, ó gbé àwọn ìṣúra ilé Olúwa, àti àwọn ìṣúra ààfin ọba. Ó gbé gbogbo rẹ̀, pẹ̀àwọn àpáta wúrà Solomoni . 10 Bẹ́̀ ni, ọba Rehoboamu àwọn àpáta idẹ láti fi dípò wọn, ó fi èyí àwọn alákòóso àti olùṣọ́ ó ẹnu iṣẹ́ àbáwọlé ẹnu-ọ̀ààfin ọba lọ́wọ́. 11 Ìgbàkígbà ọba lọ ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ n lọ pẹ̀rẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn àpáta náà àti lẹ́yìn, wọ́n wọn padà yàrá ìṣọ́.

12 Nítorí ti Rehoboamu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ìbínú Olúwa padà kúrò lórí rẹ̀, a pa á run pátápátá. Nítòótọ́, ìre díẹ̀ Juda.

13 Ọba Rehoboamu fi ara rẹ̀ lélẹ̀ gidigidi Jerusalẹmu, ó tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ ọba. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n Jerusalẹmu, ìlú ńlá Olúwa ti yàn jáde kúrò nínú gbogbo àwọn ̀Israẹli èyí ó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni. 14 O ṣe búburú, nítorí múra nínú ọkàn rẹ̀ láti Olúwa.

15 Fún iṣẹ́ ìjọba Rehoboamu láti ìbẹ̀rẹ̀ ìparí, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Ṣemaiah wòlíì àti ti Iddo, aríran ó ṣe pẹ̀ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ àwọn baba ńlá? Ìtẹ̀síwájú ogun jíjà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu. 16 Rehoboamu sun pẹ̀àwọn baba rẹ̀ a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi. Abijah ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também