Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 34

Josiah gbógun ti ìwà ìbọ̀rìṣà

1 34.1,2: 2Ọb 22.1,2. Josiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́jọ nígbà ó jẹ ọba, ó ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n. 2 Ó ṣe ohun ó dára ojú Olúwa, ó rìn ̀baba rẹ̀ Dafidi, ọwọ́ ̀tún tàbí òsì.

3 34.3-7: 2Ọb 23.4-20. ọdún kẹjọ ìjọba rẹ̀, nígbà ó ̀dọ́mọdé, ó bẹ̀rẹ̀ í ojú Ọlọ́run baba Dafidi. ọdún kejìlá. Ó bẹ̀rẹ̀ fọ Juda àti Jerusalẹmu mọ́ kúrò ibi gíga rẹ̀, ère òrìṣà Aṣerah, àti ère yíyá àti ère dídà. 4 Lábẹ́ àpẹẹrẹ àwọn pẹpẹ Baali ni a lulẹ̀, ó fọ́ àwọn ère wẹ́wẹ́, ó run àwọn pẹpẹ ó lórí rẹ̀, wọ́n fọ́ túútúú, àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà. Èyí ó fọ́ wọn lúúlúú, ó gbọ̀n wọ́n orí isà òkú àti àwọn ó ń ẹbọ wọn. 5 Ó sun àwọn egungun àwọn àlùfáà lórí pẹpẹ wọn, bẹ́̀ ni ó wẹ Juda àti Jerusalẹmu mọ́. 6 ìlú Manase, Efraimu àti Simeoni, àní títí ó fi Naftali, àti nínú àwọn, ó ilé wọn yíkákiri. 7 Ó pẹpẹ àti ère Aṣerah lulẹ̀ àti àwọn ère yíyá àti àwọn òrìṣà, ó gùn ó ti gbogbo àwọn ère orí pẹpẹ lulẹ̀ gbogbo àyíká Israẹli. Lẹ́yìn náà ó padà Jerusalẹmu.

8 34.8-12: 2Ọb 22.3-7. ọdún kejìdínlógún ìjọba Josiah ni a ti wẹ ilẹ̀ náà mọ́ àti ilé Olúwa, ó rán Ṣafani ọmọ Asalia àti Maaseiah olórí ìlú náà, pẹ̀Joah, ọmọ Joahasi, akọ̀, láti tún ilé Olúwa Ọlọ́run ṣe.

9 Wọ́n lọ ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, ó fún un owó náà ó inú ilé Ọlọ́run, ti àwọn ọmọ Lefi ẹni ó jẹ́ aṣọ́bodè ti gbà láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn Manase Efraimu àti láti ̀dọ̀ àwọn ìyókù Israẹli àti ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn Juda àti Benjamini wọ́n padà Jerusalẹmu. 10 Nígbà náà ni wọn fi le àwọn ń ṣiṣẹ́ ilé lọ́wọ́, àwọn ń ṣe alábojútó iṣẹ́ ilé Olúwa. Àwọn ọkùnrin yìí san owó fún àwọn òṣìṣẹ́ ó ń túnṣe, wọ́n ń ṣiṣẹ́ ilé Olúwa. 11 Wọ́n tún fi owó fún àwọn oníṣọ̀àti àwọn olùkọ́láti ra òkúta gbígbẹ́ àti ìtì igi fún ìsopọ̀ àti igi rírẹ́ fún ìkọ́ọba Juda ti gbà láti túnṣe.

12 Àwọn ọkùnrin náà ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀òtítọ́, láti darí wọn Jahati àti Obadiah, àwọn ọmọ Lefi láti Merari, àti Sekariah àti Meṣullamu, sọ̀kalẹ̀ láti Kohati àwọn ọmọ Lefi gbogbo ó ọgbọ̀n ohun èlò orin. 13 Wọ́n olórí àwọn aláàárù àti àwọn alábojútó gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ láti ibi iṣẹ́ ibi iṣẹ́, díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Lefi akọ̀, olùtọ́àti olùṣọ́.

A ìwé òfin

14 Nígbà wọ́n owó náà wọ́n ilé Olúwa, Hilkiah àlùfáà ìwé òfin Olúwa a ti fi fún un láti ọwọ́ Mose. 15 Hilkiah fún Ṣafani akọ̀, "Èmi ti ìwé òfin nínú ilé Olúwa." Ó fi fún Ṣafani.

16 Nígbà náà Ṣafani ìwé náà lọ ̀dọ̀ ọba ó ròyìn fún un. "Àwọn ìjòyè rẹ̀ ń ṣe gbogbo nǹkan a ti fi wọn lọ́wọ́. 17 Wọ́n ti san owó náà ó nínú ilé Olúwa wọ́n ti fi àwọn alábojútó lọ́wọ́ àti àwọn òṣìṣẹ́." 18 Nígbà náà Ṣafani akọ̀sọ fún ọba, "Hilkiah àlùfáà ti fún mi ìwé." Ṣafani níwájú ọba.

19 Nígbà ọba gbọ́ ̀rọ̀ òfin, ó fa aṣọ rẹ̀ ya. 20 Ó pa àṣẹ yìí fún Hilkiah, Ahikamu ọmọ Ṣafani, Abdoni ọmọ Mika, Ṣafani akọ̀àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba. 21 "lọ lọ béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi nípa àwọn ìyókù Israẹli àti Juda nípa ohun wọ́n kọ sínú ìwé yìí a ti . Títóbi ni ìbínú Olúwa ó ti jáde orí wa nítorí àwọn baba wa ti pa ̀rọ̀ Olúwa mọ́, wọn ì ṣe gẹ́gẹ́ i gbogbo èyí a kọ sínú ìwé yìí."

22 Hilkiah àti àwọn ènìyàn ọba yàn tọ Hulda wòlíì obìnrin láti ba sọ̀rọ̀, ẹni ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tokhati a tún ń Tikfa, ọmọ Harhasi, olùtọ́ibi ìkáṣọsí. Ó ń gbé Jerusalẹmu, ìhà kejì.

23 Ó fún wọn , "Èyí ni ohun Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ti sọ, sọ fún àwọn ọkùnrin ó rán mi , 24 Èyí ni ohun Olúwa , "Èmi yóò ibi ìhín yìí àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gbogbo àní ègún a kọ sínú ìwé wọ́n ti níwájú ọba Juda." 25 Nítorí wọ́n ti kọ̀ sílẹ̀ wọ́n ti sun tùràrí ọlọ́run mìíràn wọ́n ti mi bínú pẹ̀gbogbo ohun wọ́n ti fi ọwọ́ wọn ṣe, ìbínú yóò jáde sórí ibí yìí, a yóò paná rẹ̀.’ 26 Sọ fún ọba Juda, ẹni ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, Èyí ni ohun Olúwa ti sọ, Ọlọ́run Israẹli, sọ nípa ̀rọ̀ wọ́n ìwọ gbọ́. 27 Nítorí ọkàn rẹ̀ dúró, ìwọ rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa nígbà ó gbọ́ ohun ó sọ lórí ibí yìí àti ènìyàn rẹ, nítorí ìwọ rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú mi o fa aṣọ rẹ ya, o lọ níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ ni Olúwa . 28 Nísinsin yìí, Èmi ó jọ pọ̀ sọ́dọ̀ àwọn baba rẹ, a ó sin ́ àlàáfíà. Ojú rẹ gbogbo ibi èmi ó sórí ibí yìí àti lórí àwọn ń gbé ibẹ̀.’ "

Bẹ́̀ ni wọ́n ìdáhùn rẹ̀ padà ̀dọ̀ ọba.

29 Nígbà náà ni ọba pe gbogbo àwọn àgbàgbà Juda jọ àti Jerusalẹmu. 30 Ó gòkè lọ ilé Olúwa pẹ̀àwọn ọkùnrin Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu, àwọn àlùfáà àti àwọn Lefigbogbo àwọn ènìyàn láti ibi kéékèèké ńlá. Ó á etí ìgbọ́ wọn, gbogbo ̀rọ̀ ó nínú ìwé májẹ̀, a ti nínú ilé Olúwa. 31 Ọba dúró ipò rẹ̀ ó tún májẹ̀níwájú Olúwa, láti tẹ̀Olúwa àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, àti ̀rẹ̀ àti àṣẹ rẹ̀ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ̀ àti gbogbo àyà rẹ̀ àti láti pa ̀rọ̀ májẹ̀a kọ inú ìwé yìí.

32 Nígbà náà, ó gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu àti Benjamini dúró nínú ̀fún ara wọn, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ṣe èyí gẹ́gẹ́ bi májẹ̀Ọlọ́run, Ọlọ́run baba ńlá wọn.

33 Josiah gbogbo ohun ìríra kúrò nínú gbogbo ìlú ń ṣe ti àwọn ó Israẹli, ó gbogbo àwọn ó Israẹli sin Olúwa Ọlọ́run wọn gẹ́gẹ́ ó ti ṣe láyè wọn, kúrò láti máa tọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn lẹ́yìn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também