Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 31

1 Nígbà gbogbo nǹkan wọ̀nyí ti òpin, àwọn ọmọ Israẹli ó níbẹ̀ jáde lọ àwọn ìlú Juda, wọ́n fọ́ àwọn òkúta ìyàsọ́tọ̀ wẹ́wẹ́, wọ́n àwọn ère Aṣerah lulẹ̀. Wọ́n ba àwọn ibi gíga jẹ́ àti àwọn pẹpẹ jákèjádò Juda àti Benjamini àti Efraimu àti Manase. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti pa gbogbo wọn run, àwọn ọmọ Israẹli padà ìlú wọn àti nǹkan ìní wọn.

Ìdáwó fún ìjọ́sìn

2 Hesekiah fi àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi lọ́wọ́ àwọn ìpín olúkúlùkù wọn gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn gẹ́gẹ́ àlùfáà tàbí ará Lefi láti tẹ́ ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ láti fi ọpẹ́ fún àti láti kọ àwọn orin ìyìn ẹnu-ọ̀ibùgbé Olúwa. 3 Ọba fi sílẹ̀ láti ara ohun ìní rẹ̀ fun ẹbọ sísun àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ àti fún ẹbọ sísun ọjọ́ ìsinmi, òṣùpá tuntun àti àjọ̀dún a yàn gẹ́gẹ́ bi a ti ṣe kọ ́ nínú òfin Olúwa. 4 Ó pàṣẹ fún àwọn ènìyàn ń gbé Jerusalẹmu láti fi ìpín ó yẹ fún àlùfáà fún un àti àwọn ará Lefi, wọn ó fi ara wọn fún òfin Olúwa. 5 kété àṣẹ náà jáde lọ, àwọn ọmọ Israẹli fi tìfẹ́tìfẹ́ fi àkọ́so ti ọkà wọn, ọtí tuntun, òróró àti oyin àti gbogbo ohun pápá jáde lélẹ̀. Wọ́n ̀pọ̀ iye, àti ìdámẹ́wàá gbogbo nǹkan . 6 Àwọn ọkùnrin Israẹli àti Juda ti gbe inú àwọn ìlú Juda pẹ̀ìdámẹ́wàá agbo ẹran àti ohun èlò àti ohun ̀sìn àti ìdámẹ́wàá ti àwọn nǹkan mímọ́ a ti sọ́tọ̀ Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n wọn jọ òkìtì. 7 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe èyí oṣù kẹta, wọ́n parí oṣù keje. 8 Nígbà Hesekiah àti àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ , wọ́n òkìtì náà, wọ́n yin Olúwa, pẹ̀ìbùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli.

9 Hesekiah béèrè lọ́wọ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi nípa òkìtì; 10 àti Asariah olórí àlùfáà ti ìdílé Sadoku dáhùn , "ìwọ̀n ìgbà àwọn ènìyàn ti bẹ̀rẹ̀ ìdáwó wọn ilé Olúwa àti èyí yóò jẹ àti ̀pọ̀ láti tọ́pamọ́ nítorí Olúwa ti bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀, ó ṣẹ́lọ́pọ̀lọ́pọ̀."

11 Hesekiah pàṣẹ láti tọ́àwọn yàrá ìṣúra nínú ilé Olúwa, wọ́n ṣe èyí. 12 Nígbà náà wọ́n ọrẹ àti ìdámẹ́wàá àti àwọn ̀bùn a mímọ́ wọ ilé náà nítòótọ́. Lórí èyí Konaniah ọmọ Lefi, ń ṣe olórí, Ṣimei arákùnrin rẹ̀ ni igbákejì rẹ̀. 13 Jehieli, Asasiah, Nahati, Asaheli, Jerimoti, Josabadi, Elieli, Ismakia, Mahati àti Benaiah jẹ́ àwọn alábojútó lábẹ́ Konaniah àti Ṣimei arákùnrin rẹ̀ nípa ipá ọba Hesekiah àti Asariah olórí ti ó ìkáwọ́ ilé Ọlọ́run.

14 Kore ọmọ Imina ará Lefi olùtọ́ẹnu-ọ̀ìlà-oòrùn, ìkáwọ́ àwọn ọrẹ àtinúwá a fi fún Ọlọ́run, o ń pín ìdáwó a ṣe fún Olúwa pẹ̀àwọn ̀bùn a sọ́tọ̀ 15 Edeni, Miniamini, Jeṣua, Ṣemaiah, Amariah àti Ṣekaniah ràn án lọ́wọ́ tọkàntọkàn nínú àwọn ìlú àwọn àlùfáà ń dáwó fún àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ wọn gẹ́gẹ́ ìpín wọn, àgbà àti kékeré.

16 àfikún, wọ́n pín àwọn ọkùnrin àgbà ọdún mẹ́ta tàbí ̀pọ̀ orúkọ wọn nínú ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ baba ńlá wọn. Gbogbo àwọn ti yóò wọ ilé Olúwa láti ṣe oríṣìí iṣẹ́ ti a gbà wọ́n fún gẹ́gẹ́ ìgbẹ́kẹ̀wọn àti ìpín wọn. 17 Wọ́n pín àwọn àlùfáà, wọn kọ orúkọ àwọn ìdílé wọn sínú ìtàn ìdílé àti àwọn ará Lefi ogún ọdún tàbí bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ìpinnu àti ìpín wọn. 18 Wọ́n fi gbogbo àwọn ọmọ kéékèèké i, àwọn ìyàwó, àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin gbogbo ará ìlú a kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé ti baba ńlá wọn fún ìrántí. Nítorí wọ́n ṣe òtítọ́ yíya ara wọn ̀tọ̀.

19 ti àwọn àlùfáà, àwọn ìran ọmọ Aaroni, ń gbé ni àwọn ilẹ̀ oko lẹ́bàá àwọn ìlú wọn tàbí àwọn ìlú mìíràn. A yan àwọn ọkùnrin pẹ̀orúkọ láti pín ìlú fún gbogbo ọkùnrin láàrín wọn àti gbogbo àwọn a kọ sínú ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ baba ńlá àwọn ará Lefi.

20 Èyí ni Hesekiah ṣe jákèjádò Juda, ó ṣe ohun ó dára àti ó tọ́ àti ohun òtítọ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. 21 Nínú ohun gbogbo ó dáwọ́ti iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Ọlọ́run àti ìgbọ́ràn òfin àti àwọn àṣẹ. Ó Ọlọ́run rẹ̀, ó ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn. Ó ṣe rere.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também