Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 20

Jehoṣafati pa Moabu àti Amoni run

1 Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ Moabu àti àwọn ọmọ Ammoni àti díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Mehuni láti gbé ogun ti Jehoṣafati.

2 Àwọn díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin láti sọ fún Jehoṣafati, "Àwọn ̀pọ̀ ̀wọ́ ogun ń bọ̀ láti apá kejì Òkun láti Siria. Ó ti Hasason Tamari náà" (èyí í ṣe En-Gedi). 3 Nípa ìró ìdágìrì, Jehoṣafati pinnu láti wádìí lọ́wọ́ Olúwa, ó kéde àwẹ̀ kíákíá fún gbogbo Juda. 4 Àwọn ènìyàn Juda ara wọn jọ pọ̀ láti ìrànlọ́wọ́ láti ̀dọ̀ Olúwa; pẹ̀lúpẹ̀, wọ́n láti gbogbo ìlú Juda láti a.

5 Nígbà náà Jehoṣafati dìde dúró níwájú àpéjọ Juda àti Jerusalẹmu ilé Olúwa níwájú àgbàlá tuntun. 6 O ,

"Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wa, ìwọ ha ṣe Ọlọ́run ń bẹ ̀run? Ìwọ ń ṣe alákòóso lórí gbogbo ìjọba àwọn orílẹ̀-èdè. Agbára àti ipá ń bẹ ọwọ́ rẹ, ẹnìkan ó ́ lójú. 7 20.7: Jk 2.23.Ìwọ ha kọ́ Ọlọ́run wa, o ti àwọn olùgbé ilẹ̀ yìí jáde níwájú àwọn ènìyàn Israẹli, o fi fún irú-ọmọ Abrahamu ̀rẹ́ rẹ láéláé? 8 Wọ́n ti ń gbé nínú rẹ̀ wọ́n ti kọ́ sínú rẹ ibi mímọ́ fún orúkọ rẹ , 9 ibi orí wa, bóyá idà ìjìyà tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn àwọn yóò dúró níwájú rẹ níwájú ilé yìí ń jẹ́ orúkọ rẹ, àwa yóò sọkún jáde, ìwọ yóò gbọ́ wa. Ìwọ yóò gbà ?

10 "Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, àwọn ọkùnrin nìyí láti Ammoni, Moabu àti òkè Seiri, agbègbè ibi ti ìwọ ti gba àwọn ọmọ Israẹli láyè láti gbóguntì nígbà wọn láti Ejibiti, bẹ́̀ ni wọ́n yípadà kúrò ̀dọ̀ wọn, wọn pa wọ́n run. 11 kíyèsi i, wọ́n ti san án padà fún wa; láti wa jáde kúrò nínú ìní rẹ, ìwọ ti fi fún wa láti . 12 Ọlọ́run wa, ṣé ìwọ ṣe ìdájọ́ fún wọn? Nítorí àwa agbára láti dojúkọ àwọn ̀pọ̀ ogun ńlá yìí ń bọ̀ wa. Àwa mọ̀ ohun yẹ ṣe, ṣùgbọ́n ojú wa ̀dọ̀ rẹ."

13 Gbogbo àwọn ọkùnrin Juda, pẹ̀àwọn aya wọn àti ọmọ wọn àti àwọn kéékèèké, dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa.

14 Nígbà náà, ̀Olúwa Jahasieli ọmọ Sekariah, ọmọ Benaiah, ọmọ Jeieli, ọmọ Mattaniah ọmọ Lefi àti ọmọ Asafu, gẹ́gẹ́ ó ṣe dìde dúró láàrín àpéjọ ènìyàn.

15 Ó , "tẹ́sílẹ̀, ọba Jehoṣafati àti gbogbo àwọn ń gbé Juda àti Jerusalẹmu! Èyí ohun Olúwa sọ a ṣe: ṣe bẹ̀tàbí fòyà nítorí ̀pọ̀ ogun ńlá yìí. Nítorí ogun náà í ṣe tiyín, ṣùgbọ́n ti Ọlọ́run ni. 16 ̀la, sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n lọ, wọn yóò gòkè pẹ̀, ̀yin yóò wọn ìpẹ̀kun odò náà, níwájú aginjù Jerueli. 17 ̀yin láti ogun yìí . dúró ààyè yín; dúró jẹ́́ ìgbàlà Olúwa yóò fi fún yín, ìwọ Juda àti Jerusalẹmu. ṣe bẹ̀; ṣe fòyà. jáde lọ láti lọ dojúkọ wọ́n ̀la, Olúwa yóò pẹ̀yín.’ "

18 Jehoṣafati tẹ orí rẹ̀ ba sílẹ̀ pẹ̀ojú rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu wólẹ̀ níwájú láti sin Olúwa. 19 Nígbà náà díẹ̀ lára àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ọmọ Kohati àti àwọn ọmọ Kora dìde dúró wọ́n sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pẹ̀ohùn ariwo ńlá.

20 òwúrọ̀ kùtùkùtù wọ́n jáde lọ aginjù Tekoa. Gẹ́gẹ́ wọ́n ti ń jáde lọ, Jehoṣafati dìde dúró ó , "gbọ́ mi, Juda àti ènìyàn Jerusalẹmu! ìgbàgbọ́ nínú Olúwa Ọlọ́run yín ̀yin yóò borí, ìgbàgbọ́ nínú àwọn wòlíì rẹ̀ ̀yìn yóò ṣe rere." 21 Lẹ́yìn ìgbà ó àwọn ènìyàn náà gbèrò tán, Jehoṣafati yàn wọ́n láti kọrin Olúwa àti láti fi ìyìn fún ẹwà ìwà mímọ́ gẹ́gẹ́ ó ń jáde lọ iwájú ogun ńlá náà, ,

"fi ọpẹ́ fún Olúwa,

nítorí àánú rẹ̀ dúró títí láéláé."

22 wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ kọrin àti ìyìn, Olúwa rán ogun ̀yìn àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu àti òkè Seiri ó ń gbógun ti Juda, wọ́n kọlù wọ́n. 23 Àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu dìde dúró àwọn ọkùnrin ń gbé òkè Seiri láti pa wọ́n run túútúú. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti pa àwọn ọkùnrin láti òkè Seiri, wọ́n ran ra wọn lọ́wọ́ láti pa ara wọn run.

24 Nígbà àwọn ènìyàn Juda jáde ìhà ilé ìṣọ́ aginjù, wọn ń wo àwọn ̀pọ̀ ènìyàn, òkú nìkan ni wọ́n ó ṣubú ilẹ̀, ẹnìkan ó ààyè . 25 Bẹ́̀ ni Jehoṣafati àti àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ láti ìkógun wọn, wọ́n lára wọn ̀pọ̀ iyebíye ọrọ̀ púpọ̀, ó ju èyí wọ́n lọ. ̀pọ̀ ìkógun níbẹ̀, èyí ó gbà wọ́n ọjọ́ mẹ́ta láti gbà pọ̀. 26 ọjọ́ kẹrin, wọn ara jọ pọ̀ àfonífojì ìbùkún, níbi wọ́n ti ń fi ìbùkún fún Olúwa. Ìdí nìyí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ àfonífojì ìbùkún títí di òní.

27 Nígbà náà wọ́n darí pẹ̀Jehoṣafati, gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu padà pẹ̀ayọ̀ Jerusalẹmu, nítorí Olúwa ti fún wọn ìdí láti yọ̀ lórí àwọn ̀wọn. 28 Wọ́n wọ Jerusalẹmu, wọ́n lọ ilé Olúwa pẹ̀ohun èlò orin olókùn àti dùùrù àti ìpè.

29 Ìbẹ̀Ọlọ́run si orí gbogbo ìjọba ilẹ̀ náà nígbà wọ́n gbọ́ Olúwa ti àwọn ̀Israẹli . 30 Bẹ́̀ ni ìjọba Jehoṣafati àlàáfíà, nítorí Ọlọ́run rẹ̀ ti fún un ni ìsinmi gbogbo àyíká.

Òpin ìjọba Jehoṣafati

31 20.31-33: 1Ọb 22.41-43. Báyìí ni Jehoṣafati jẹ ọba lórí Juda. Ó jẹ́ ẹni ọdún márùndínlógójì. Nígbà ó di ọba Juda, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Asuba ọmọbìnrin Silihi. 32 Ó rin ̀baba rẹ̀ Asa kúrò nínú rẹ̀, ó ṣe èyí ó tọ́ ojú Olúwa. 33 ibi gíga, pẹ̀lúpẹ̀, mu wọn kúrò, gbogbo àwọn ènìyàn náà fi ọkàn wọn fún Ọlọ́run àwọn baba wọn.

34 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoṣafati, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí òpin, ni a kọ inú ìwé ìtàn ti Jehu ọmọ Hanani, a kọ inú ìwé àwọn ọba Israẹli.

35 20.35-37: 1Ọb 22.48,49. Nígbà ó , Jehoṣafati ọba Juda da ara rẹ̀ pọ̀ pẹ̀Ahasiah, ọba Israẹli, ẹni ó jẹ̀bi ìwà búburú. 36 Ó gbà pẹ̀rẹ̀ láti kan ọkọ̀ láti lọ Tarṣiṣi, lẹ́yìn èyí wọ́n kan ọkọ̀ Esioni-Geberi. 37 Elieseri ọmọ Dodafahu ti Meraṣa sọtẹ́lẹ̀ Jehoṣafati, pe, "Nítorí ìwọ ti da ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ Ahasiah, Olúwa yóò pa ohun ti ìwọ ti ṣe run." Àwọn ọkọ̀ náà fọ́, wọn le lọ ibi ìtajà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também