Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 16

Ìṣọ̀tẹ̀ Kora, Datani àti Abiramu

1 Kora ọmọ Isari, ọmọ Kohati, ọmọ Lefi àwọn ọmọ Reubeni: Datani àti Abiramu, àwọn ọmọ Eliabu, àti Oni ọmọ Peleti ènìyàn mọ́ra. 2 Wọ́n dìde Mose, pẹ̀àádọ́ta nígba (250) ọkùnrin nínú àwọn ọmọ Israẹli, ìjòyè nínú ìjọ, àwọn olórúkọ nínú àjọ, àwọn ọkùnrin olókìkí. 3 Wọ́n ara wọn jọ láti tako Mose àti Aaroni, wọ́n sọ fún wọn , "ti kọjá ààyè yín, ó gẹ́́! Mímọ́ ni gbogbo ènìyàn, ẹni mọ́ láàrín wọn, Olúwa pẹ̀wọn, nítorí ni ̀yin ṣe gbé ara yín ga ju ìjọ ènìyàn Olúwa lọ?"

4 Nígbà Mose gbọ́ èyí, ó dojúbolẹ̀, 5 16.5: 2Tm 2.19.Ó sọ fún Kora àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ̀ , "̀la ni Olúwa yóò fi ẹni í ṣe tirẹ̀ àti ẹni mọ́ hàn, yóò ẹni náà súnmọ́ òun. Ẹni ó yàn ni yóò ó súnmọ́ òun. 6 Kora àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ̀ ṣe èyí, àwo tùràrí. 7 fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀ lọ́la níwájú Olúwa, yóò ṣe, ọkùnrin Olúwa yàn òun ni. ̀yin ọmọ Lefi, ti kọjá ààyè yín!"

8 Mose tún sọ fún Kora , "gbọ́ báyìí o, ̀yin ọmọ Lefi! 9 ha tọ́ fún yín Ọlọ́run Israẹli ti yín sọ́tọ̀ lára ìjọ Israẹli yòókù, yín súnmọ́ ara rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ Olúwa àti láti dúró ṣiṣẹ́ ìsìn níwájú àwọn ènìyàn? 10 Ó ti àwọn ènìyàn yín jẹ́ ọmọ Lefi súnmọ́ ara rẹ̀, ṣùgbọ́n báyìí tún ń ọnà láti ṣiṣẹ́ àlùfáà. 11 Olúwa ni ìwọ àti gbogbo ẹlẹgbẹ́ rẹ takò. Ta a ni Aaroni jẹ́ ̀yin ó fi kùn i?"

12 Mose ránṣẹ́ Datani àti Abiramu àwọn ọmọ Eliabu. Ṣùgbọ́n wọ́n , "Àwa í ! 13 ha gẹ́́ o ti wa jáde láti ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin láti pa sínú aginjù yìí? O tún fẹ́ sọ ara rẹ di olúwa wa lórí ? 14 Síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ ì wa ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin, bẹ́̀ ni o pín ilẹ̀ ìní àti ọgbà àjàrà. Ìwọ ha fẹ́ sọ di ẹrú ? Rárá o, àwa yóò gòkè !"

15 Nígbà náà ni Mose bínú gidigidi, ó sọ fún Olúwa , "ṣe gba ọrẹ wọn, èmi gba kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ lọ́wọ́ wọn, bẹ́̀ ni n pa ẹnikẹ́ni nínú wọn lára!"

16 Mose sọ fún Kora , "Ìwọ àti ọmọ lẹ́yìn rẹ gbọdọ̀ fi ara hàn níwájú Olúwa lọ́lagbogbo yín, ìwọ, àwọn ọmọ lẹ́yìn rẹ àti Aaroni. 17 ẹnìkọ̀̀kan yín àwo tùràrí, ó fi tùràrí sínú rẹ̀, gbogbo rẹ̀ jẹ́ àádọ́ta nígba (250) àwo tùràrí ko síwájú Olúwa. Ìwọ àti Aaroni yóò àwo tùràrí pẹ̀." 18 Nígbà náà ni oníkálùkù wọn àwo tùràrí, wọ́n fi iná àti tùràrí i nínú, wọ́n dúró ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, àwọn pẹ̀Mose àti Aaroni. 19 Nígbà Kora gbogbo àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ jọ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, ògo Olúwa farahan gbogbo ìjọ ènìyàn. 20 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 21 "ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín ìjọ wọ̀nyí, ń ba à le pa wọ́n run lẹ́̀kan náà."

22 Ṣùgbọ́n Mose àti Aaroni dojúbolẹ̀ wọ́n kígbe sókè , "Ọlọ́run, Ọlọ́run ̀gbogbo ènìyàn, Ìwọ ó wa bínú gbogbo ìjọ ènìyàn nígbà jẹ́ ẹnìkan ṣẹ̀?"

23 Olúwa tún sọ fún Mose , 24 "Sọ fún ìjọ ènìyàn , wọ́n jìnnà àgọ́ Kora, Datani àti Abiramu.’ "

25 Mose dìde lọ Datani àti Abiramu àwọn àgbàgbà Israẹli tẹ̀. 26 Ó kìlọ̀ fún ìjọ ènìyàn , "kúrò àgọ́ àwọn ènìyàn búburú yìí! ṣe fọwọ́ kan ohun kan í ṣe tiwọn ba à parun nítorí ̀ṣẹ̀ wọn." 27 Àwọn ènìyàn sún kúrò àgọ́ Kora, Datani àti Abiramu. Datani àti Abiramu jáde, àwọn ìyàwó wọn àti àwọn ọmọ wọn dúró ẹnu-ọ̀àgọ́ wọn.

28 Nígbà náà ni Mose , "Báyìí ni ó ṣe mọ̀ Olúwa rán mi láti ṣe gbogbo iṣẹ́ wọ̀nyí àti í ṣe ìfẹ́ inú mi ni àwọn ohun ń ṣe. 29 àwọn ènìyàn yìí gbogbo ènìyàn ti ń , ìrírí wọn yàtọ̀ ti àwọn ènìyàn yòókù, a jẹ́ í ṣe Olúwa rán mi. 30 Ṣùgbọ́n Olúwa ṣe ohun tuntun, ilẹ̀ la ẹnu, gbé wọn , àwọn pẹ̀gbogbo ohun wọ́n , wọ́n wọ inú ibojì wọn lọ láààyè, nígbà náà ni ̀yin ó mọ̀ àwọn ènìyàn yìí ti kẹ́gàn Olúwa."

31 ó ṣe parí ̀rọ̀ wọ̀nyí, ilẹ̀ pín méjì nísàlẹ̀ wọn, 32 ilẹ̀ lanu ó gbé wọn pẹ̀gbogbo ará ilé wọn àti àwọn ènìyàn Kora àti gbogbo ohun wọ́n . 33 Gbogbo wọn sọ̀kalẹ̀ sínú ibojì wọn láààyè pẹ̀ohun gbogbo wọ́n , ilẹ̀ padé mọ́ wọn, wọ́n ṣègbé kúrò láàrín ìjọ ènìyàn. 34 Gbogbo ènìyàn Israẹli ó wọn sálọ àwọn yòókù gbọ́ igbe wọn, wọ́n , "Ilẹ̀ yóò gbé àwa náà pẹ̀."

35 Iná jáde láti ̀dọ̀ Olúwa ó run àádọ́ta nígba (250) ọkùnrin wọ́n tùràrí .

36 Olúwa sọ fún Mose , 37 "Sọ fún Eleasari ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà, ó àwọn àwo tùràrí jáde kúrò nínú iná nítorí wọ́n jẹ́ mímọ́, ó tan iná náà káàkiri ibi jìnnà. 38 Èyí ni àwo tùràrí àwọn ó nítorí ̀ṣẹ̀ wọn. gún àwo tùràrí yìí, fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ, wọ́n jẹ́ mímọ́ nítorí wọ́n ti wọn síwájú Olúwa. wọ́n jẹ́ àmì fún àwọn ọmọ Israẹli."

39 Eleasari í ṣe àlùfáà gbogbo àwo tùràrí àwọn ó jóná wa, ó gún wọn pọ̀, ó fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ, 40 gẹ́gẹ́ Olúwa ṣe sọ láti ẹnu Mose. Èyí yóò jẹ́ ohun ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli , àlejò yàtọ̀ irú-ọmọ Aaroni gbọdọ̀ tùràrí níwájú Olúwa, ẹni ó ṣe bẹ́̀, yóò dàbí Kora àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀.

41 ọjọ́ kejì gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli kùn Mose àti Aaroni , "ti pa àwọn ènìyàn Olúwa."

42 Ṣùgbọ́n nígbà gbogbo ìjọ ènìyàn péjọ lòdì Mose àti Aaroni, níwájú àgọ́ ìpàdé, lójijì ni ìkùùkuu bolẹ̀, ògo Olúwa fi ara hàn. 43 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni lọ síwájú àgọ́ ìpàdé, 44 Olúwa sọ fún Mose , 45 "Yàgò kúrò láàrín ìjọ ènìyàn yìí, ń ba le run wọ́n ìṣẹ́kan." Wọ́n dojúbolẹ̀.

46 Mose sọ fún Aaroni , "àwo tùràrí, o fi iná i lórí pẹpẹ, fi tùràrí sínú rẹ̀, o tètè mu lọ àárín ìjọ ènìyàn láti ṣe ètùtù fún wọn nítorí ìbínú Olúwa ti jáde, àjàkálẹ̀-ààrùn ti bẹ̀rẹ̀." 47 Aaroni ṣe Mose ti , ó sáré lọ àárín àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n àjàkálẹ̀-ààrùn ti bẹ̀rẹ̀ láàrín wọn, ṣùgbọ́n Aaroni fín tùràrí, ó ṣe ètùtù fún wọn. 48 Ó dúró láàrín àwọn alààyè àti òkú, àjàkálẹ̀-ààrùn náà dúró. 49 Ṣùgbọ́n àjàkálẹ̀-ààrùn ti pa ẹgbàá méje ó lẹ̀́dẹ́gbẹ̀rin (14,700) ènìyàn àfikún àwọn ó níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Kora. 50 Aaroni padà tọ Mose lọ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn náà ti dúró.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também