Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 9

Àsè ìrékọjá

1 9.1-5: El 12.1-14,21-28. Olúwa sọ fún Mose nínú aginjù Sinai oṣù kìn-ín-ní ọdún kejì lẹ́yìn wọ́n kúrò ilẹ̀ Ejibiti , 2 "àwọn ọmọ Israẹli máa pa àjọ ìrékọjá mọ́ àsìkò rẹ̀. 3 ṣe é àsìkò rẹ̀ gan an ìdajì ọjọ́ kẹrìnlá oṣù yìí ìbámu pẹ̀àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀."

4 Mose sọ fún àwọn ọmọ Israẹli wọ́n máa pa àjọ ìrékọjá mọ́. 5 Wọ́n ṣe àjọ ìrékọjá aginjù Sinai ìdajì ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní. Àwọn ọmọ Israẹli ṣe gbogbo nǹkan gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

6 Àwọn díẹ̀ nínú wọn ṣe àjọ ìrékọjá lọ́jọ́ náà nítorí wọ́n di aláìmọ́ nítorí òkú ènìyàn. Nítorí èyí wọ́n sọ́dọ̀ Mose àti Aaroni lọ́jọ́ náà. 7 Wọ́n sọ fún Mose , "A di aláìmọ́ nípa òkú ènìyàn, ṣùgbọ́n a fi í le è fi ọrẹ wa fún Olúwa pẹ̀àwọn ará Israẹli yòókù àsìkò a ti yàn."

8 Mose wọn lóhùn , "dúró n ba mọ ohun Olúwa yóò pàṣẹ nípa yín."

9 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , 10 "Sọ fún àwọn ará Israẹli: ẹnìkan nínú yín tàbí nínú ìran yín di aláìmọ́ nípa òkú ènìyàn tàbí ó lọ ìrìnàjò síbẹ̀ yóò pa àjọ ìrékọjá Olúwa mọ́. 11 Wọn yóò ṣe tiwọn ìdajì ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì. Wọn yóò jẹ ẹran náà, pẹ̀àkàrà aláìwú àti ewúro. 12 9.12: Ek 12.46; Jh 19.36.Wọn gbọdọ̀ ṣẹ́ ̀kankan di àárọ̀, wọn gbọdọ̀ ṣẹ́ eegun rẹ̀. Wọ́n gbọdọ̀ tẹ̀gbogbo ìlànà fún ṣíṣe àjọ ìrékọjá. 13 Ṣùgbọ́n ẹnìkan mímọ́ lọ ìrìnàjò kọ̀ láti pa àjọ ìrékọjá mọ́, irú ẹni bẹ́̀ ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀ nítorí ọrẹ Olúwa àsìkò ó yẹ. Ẹni náà yóò ru ̀bi ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

14 " àlejò ń gbé láàrín yín fẹ́ ṣe àjọ ìrékọjá Olúwa, ó gbọdọ̀ pa á mọ́ ìbámu pẹ̀ìlànà àti òfin rẹ̀. Ìlànà kan náà ni fún àlejò àti àwọn ọmọ bíbí ilẹ̀ yín.’ "

Ìkùùkuu lórí àgọ́

15 9.15-23: El 40.36-38. ọjọ́ wọ́n gbé àgọ́ , èyí í ṣe àgọ́ ̀, dúró, ìkùùkuu àwọsánmọ̀ ó mọ́lẹ̀. Ìkùùkuu náà dàbí iná orí àgọ́ láti ìrọ̀lẹ́ títí di òwúrọ̀. 16 Bẹ́̀ ni ó nígbà gbogbo; ìkùùkuu ó, àti alẹ́ ìrísí rẹ̀ dàbí iná. 17 Nígbàkígbà ìkùùkuu yìí sókè kúrò lórí àgọ́ ni àwọn ọmọ Israẹli yóò dìde láti máa lọ; ibikíbi ìkùùkuu náà dúró ni àwọn ọmọ Israẹli yóò pa ibùdó wọn . 18 Nípa àṣẹ Olúwa ni àwọn ọmọ Israẹli ń jáde lọ, nípa àṣẹ Olúwa náà ni wọ́n ń pa ibùdó wọn. Nígbà ìkùùkuu dúró sórí àgọ́, àwọn náà yóò dúró ibùdó. 19 Nígbà ìkùùkuu dúró sórí àgọ́ fún ìgbà pípẹ́, síbẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli gbọ́rọ̀ àṣẹ Olúwa wọn gbéra láti lọ. 20 Ìgbà mìíràn ìkùùkuu lórí àgọ́ fún ọjọ́ díẹ̀; síbẹ̀ àṣẹ Olúwa, wọn yóò dúró ibùdó, ó tún , àṣẹ rẹ̀ náà ni wọn yóò gbéra. 21 Ìgbà mìíràn ìkùùkuu dúró láti ìrọ̀lẹ́ di àárọ̀, nígbà ṣí kúrò àárọ̀, wọn ó gbéra. Ìbá à ṣe ̀sán tàbí òru, ìgbàkígbà ìkùùkuu kúrò náà ni wọn ó gbéra. 22 Ìbá à ṣe fún ọjọ́ méjì, oṣù kan tàbí ọdún kan ni ìkùùkuu fi dúró sórí àgọ́, àwọn ọmọ Israẹli yóò dúró ibùdó wọn, wọn gbéra; ṣùgbọ́n nígbà ó lọ sókè ni wọn ó o gbéra. 23 Nípa àṣẹ Olúwa ni wọ́n ń pa ibùdó wọn, nípa àṣẹ Olúwa náà ni wọ́n ń gbéra. Wọ́n gbọ́rọ̀ àṣẹ Olúwa ìbámu pẹ̀àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também