Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 18

Iṣẹ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi

1 Olúwa sọ fún Aaroni , "Ìwọ, àti àwọn ọmọ rẹ àti ìdílé baba rẹ ni yóò ru gbogbo ̀ṣẹ̀ wọ́n ti fún ilé a mímọ́ fún Ọlọ́run, àti ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ nìkan ni yóò máa ru ̀ṣẹ̀ iṣẹ́ àlùfáà yín. 2 o àwọn ènìyàn rẹ ará Lefi láti ̀ìran rẹ láti dàpọ̀ mọ́ ìwọ láti ràn ́ lọ́wọ́ nígbà ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ níwájú Àgọ́ ̀. 3 18.3,4,23: Nu 1.50-53; 3.5-8,21-37; 4.1-33; 8.19.Àwọn ni ó yẹ láti dúró fún àti láti ṣe gbogbo iṣẹ́ ti Àgọ́, ṣùgbọ́n wọn gbọdọ̀ súnmọ́ ibi a ti ṣe lọ́ṣọ̀́ a mímọ́ tàbí ibi pẹpẹ, tàbí gbogbo wọn àti ìwọ máa . 4 Ó yẹ wọ́n darapọ̀ mọ́ láti jẹ ìyà iṣẹ́ fún àìtọ́ibi ti àgọ́ ìpàdé àti gbogbo iṣẹ́ ó ibi àgọ́, àti àlejò ó le ̀gbẹ́ ibi o .

5 "o mójútó iṣẹ́ ibi mímọ́ àti iṣẹ́ ibi pẹpẹ, ìbínú ba orí àwọn ọmọ Israẹli mọ́. 6 Èmi fúnra mi ti yan àwọn arákùnrin rẹ í ṣe ọmọ Lefi kún àwọn ọmọ Israẹli yòókù, wọn jẹ́ ̀bùn fún , èyí ni a fún Olúwa láti ṣe iṣẹ́ ó àgọ́ ìpàdé. 7 Ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ni yóò mójútó iṣẹ́ àlùfáà yín fún gbogbo ohun jẹ mọ́ ibi pẹpẹ àti ti ̀yin aṣọ títa, ó máa ṣiṣẹ́ ibi pẹpẹ àti nínú aṣọ a ta. Mo fún iṣẹ́ àlùfáà gẹ́gẹ́ ̀bùn. Ṣùgbọ́n àlejò ó súnmọ́ tòsí ibi ìyàsímímọ́ fún Ọlọ́run ni a ó pa."

Ẹbọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi

8 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Aaroni , "Èmi fúnra mi ti fi ́ ṣọ́ ìdí gbogbo ẹbọ a fún gbogbo ọrẹ mímọ́ àwọn ọmọ Israẹli fún mi, mo fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ gẹ́gẹ́ ìpín rẹ yóò máa ṣe. 9 Ìwọ ni o ni ìpín ọrẹ mímọ́ jùlọ a kúrò ibi iná, nínú gbogbo ọrẹ wọ́n gẹ́gẹ́ ẹbọ mímọ́ jùlọ, yálà ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ ̀ṣẹ̀ tàbí ẹbọ ̀bi, ìpín wọ̀nyí jẹ́ ti ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ. 10 jẹ ́ ibi mímọ́ jùlọ, gbogbo ọkùnrin ni ó gbọdọ̀ jẹ ́. Ó gbọdọ̀ á mímọ́.

11 "Èyí tún jẹ́ tìrẹ pẹ̀: ohunkóhun a sọ́tọ̀ lára ̀bùn ọrẹ fífì àwọn ọmọ Israẹli. fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin gẹ́gẹ́ ìpín yóò máa ṣe déédé nínú ìdílé rẹ, o mímọ́ ni o le jẹ ́.

12 "Mo fún gbogbo òróró ó dára jùlọ àti gbogbo ọtí tuntun dáradára jùlọ àti ọkà wọ́n fún Olúwa àkọ́so ohun ̀gbìn wọn wọ́n kórè. 13 Gbogbo àkọ́so nǹkan ilẹ̀ wọ́n wọn fún Olúwa yóò jẹ́ tìrẹ. Ẹnikẹ́ni nínú ìdílé rẹ, àwọn ó jẹ́ mímọ́ nínú ìdílé rẹ jẹ ́.

14 18.14: Le 27.28. "Gbogbo nǹkan a sọ́tọ̀ fún Olúwa Israẹli jẹ́ tìrẹ. 15 Gbogbo àkọ́nínú gbogbo ohun alààyè wọ́n fún Olúwa, ìbá à jẹ́ ti ènìyàn tàbí ti ẹranko jẹ́ tìrẹ ṣùgbọ́n o gbọdọ̀ ra gbogbo àkọ́ọmọkùnrin padà àti àkọ́àwọn ẹranko aláìmọ́. 16 Nígbà wọ́n oṣù kan, o gbọdọ̀ wọ́n padà iye owó ìràpadà í ṣe ṣékélì márùn-ún fàdákà, gẹ́gẹ́ iye ṣékélì ibi mímọ́ ó wọn ìwọ̀n ogún gera.

17 "Ṣùgbọ́n o gbọdọ̀ ra àwọn àkọ́ọmọ màlúù, àgùntàn tàbí ewúrẹ́; wọ́n jẹ́ mímọ́. Wọ́n ̀jẹ̀ wọn sórí pẹpẹ o sun ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọrẹ àfinásun, ẹbọ òórùn dídùn Olúwa. 18 Ẹran wọn gbọdọ̀ jẹ́ tìrẹ, gẹ́gẹ́ igẹ̀ ọrẹ ẹbọ fífì àti itan ̀tún ṣe jẹ́ tìrẹ. 19 Ohunkóhun a ti sọ́tọ̀ nínú ọrẹ àwọn ọmọ Israẹli wọ́n fún Olúwa ni mo fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin gẹ́gẹ́ ìpín rẹ yóò máa ṣe déédé. Ó jẹ́ májẹ̀iyọ̀ láéláé níwájú Olúwa fún ìwọ àti ọmọ rẹ."

20 Olúwa sọ fún Aaroni , "O ogún nínú ilẹ̀ wọn bẹ́̀ ni ìwọ ìpín láàrín wọn; Èmi ni ìpín àti ogún rẹ láàrín àwọn ọmọ Israẹli.

21 "ti fún àwọn ọmọ Lefi gbogbo ìdámẹ́wàá Israẹli gẹ́gẹ́ ogún fún iṣẹ́ wọ́n ṣe, nígbà wọ́n ń ṣiṣẹ́ níbi àgọ́ ìpàdé. 22 Láti ìsinsin yìí àwọn ọmọ Israẹli, gbọdọ̀ súnmọ́ àgọ́ ìpàdé, wọ́n ṣe bẹ́̀, wọn yóò jẹ ìyà ̀ṣẹ̀ wọn, wọn á . 23 Àwọn ọmọ Lefi ó gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ ó nínú àgọ́ ìpàdé, wọn yóò jìyà ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n kúrò láti ṣe é. Èyí ni ìlànà láéláé fún àwọn ìran ó ń bọ̀. Wọn nígbà ogún kankan láàrín àwọn ọmọ Israẹli. 24 Kàkà bẹ́̀, mo fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ ogún wọn, ìdákan nínú ìdámẹ́wàá àwọn ọmọ Israẹli pèsè gẹ́gẹ́ ọrẹ Olúwa. Èyí ni mo nípa wọn. Wọn gba ogún kankan láàrín àwọn ọmọ Israẹli."

25 Olúwa sọ fún Mose , 26 "Sọ fún àwọn ọmọ Lefi o fún wọn : Nígbà ìdámẹ́wàá ń wọlé láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ ogún rẹ. O gbọdọ̀ ìdámẹ́wàá lára rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọrẹ Olúwa. 27 A ó ka ọrẹ rẹ gẹ́gẹ́ ọkà irúgbìn láti ilẹ̀ ìpakà tàbí wáìnì láti fún wa. 28 Báyìí ni ìwọ gan an náà yóò ọrẹ wa fún Olúwa láti ara ìdámẹ́wàá ìwọ gbà láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli. Láti ara ìdámẹ́wàá ó gbọdọ̀ ọrẹ Olúwa fún Aaroni àlùfáà. 29 Ìwọ gbọdọ̀ gẹ́gẹ́ ìpín Olúwa èyí ó dára jùlọ àti ó jẹ́ mímọ́ jùlọ lára gbogbo nǹkan wọ́n fún .

30 "Sọ fún àwọn ọmọ , Nígbà ̀yin ìpín ó dára , a ó á fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ ìkórè láti ilẹ̀ ìpakà tàbí ìfúntí yín. 31 Ìwọ àti àwọn ìdílé rẹ̀ le jẹ èyí ó ibikíbi gbogbo. Nítorí ó jẹ́ ọrẹ fún iṣẹ́ rẹ níbi àgọ́ ìpàdé. 32 Nípa ṣíṣe ìgbékalẹ̀ ìpín ó dára jùlọ o jẹ̀bi lórí ̀rọ̀ yìí, ìwọ ba ọrẹ mímọ́ àwọn ọmọ Israẹli jẹ́, ìwọ yóò .’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também